Publicidade

1 Reis 2

Dafidi pàṣẹ fún Solomoni

1 Nígbà ọjọ́ ikú Dafidi súnmọ́ etílé, ó pàṣẹ fún Solomoni ọmọ rẹ̀.

2 Ó , "Èmi ti fẹ́ lọ ̀gbogbo ayé, nítorí náà jẹ́ alágbára o fi ara rẹ hàn ọkùnrin, 3 o wòye ohun Olúwa Ọlọ́run rẹ béèrè, rìn ̀rẹ̀, o pa àṣẹ àti òfin rẹ̀ mọ́, àti ìdájọ́ rẹ, àti ̀rẹ̀ gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ nínú ìwé òfin Mose, nítorí ìwọ ó le è máa ṣe rere ohun gbogbo ìwọ ṣe, àti ibikíbi ìwọ lọ, 4 Olúwa ó pa ìlérí rẹ̀ ó sọ nípa tèmi mọ́ , àwọn ọmọ rẹ kíyèsi ̀wọn, wọ́n fi gbogbo àyà wọn àti ọkàn wọn rìn níwájú mi òtítọ́, o yóò kùnà láti ọkùnrin kan lórí ìtẹ́ Israẹli.

5 "Ìwọ pẹ̀mọ ohun Joabu ọmọ Seruiah ṣe mi àti ohun ó ṣe balógun méjì nínú àwọn ológun Israẹli, Abneri ọmọ Neri àti Amasa ọmọ Jeteri. Ó pa wọ́n, ó ta ̀jẹ̀ wọn sílẹ̀ ìgbà àlàáfíà í ti ojú ogun ó fi ̀jẹ̀ náà ara àmùrè rẹ̀ ń bẹ ̀gbẹ́ rẹ̀, àti ara sálúbàtà rẹ̀ ń bẹ ẹsẹ̀ rẹ̀. 6 Ṣe í gẹ́gẹ́ ọgbọ́n rẹ̀, ṣùgbọ́n ṣe jẹ́ ewú orí rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ lọ isà òkú àlàáfíà.

7 "Ṣùgbọ́n fi inú rere hàn àwọn ọmọ Barsillai, ti Gileadi, jẹ́ wọn lára àwọn ó ń jẹun lórí tábìlì rẹ̀. Wọ́n dúró nígbà mo kúrò níwájú Absalomu arákùnrin rẹ.

8 "Àti o rántí, Ṣimei ọmọ Gera ̀Benjamini Bahurimu pẹ̀rẹ̀, ó mi èébú ó korò ọjọ́ mo lọ Mahanaimu. Nígbà ó sọ̀kalẹ̀ pàdé mi Jordani, mo fi Olúwa búra fún un , Èmi yóò fi idà pa ́.’ 9 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ṣe kíyèsi í gẹ́gẹ́ aláìlẹ́ṣẹ̀, ọkùnrin ọlọ́gbọ́n ni ìwọ ṣe; ìwọ yóò mọ ohun ìwọ yóò ṣe i. ewú orí rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ lọ sínú isà òkú pẹ̀̀jẹ̀."

10 Nígbà náà ni Dafidi sinmi pẹ̀àwọn baba rẹ̀, a sin ín ìlú Dafidi. 11 Dafidi ti jẹ ọba lórí Israẹli ogójì ọdún, ọdún méje ni Hebroni àti ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n Jerusalẹmu. 12 2.12: 1Ki 29.23.Bẹ́̀ ni Solomoni jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi baba rẹ̀, ìjọba rẹ̀ fi ìdí múlẹ̀ gidigidi.

Ìtẹ́ ọba Solomoni fìdímúlẹ̀

13 Wàyí, Adonijah ọmọ Haggiti tọ Batṣeba, ìyá Solomoni . Batṣeba bi í , "Àlàáfíà ni o wa ?"

Ó dáhùn , "Bẹ́̀ ni, àlàáfíà ni." 14 Nígbà náà ni ó fi kún un , "Mo ohun kan láti sọ fún ."

Batṣeba , "Máa ."

15 Ó , "Gẹ́gẹ́ o ti mọ̀, ti tèmi ni ìjọba náà. Gbogbo Israẹli ti ọba wọn. Ṣùgbọ́n nǹkan yípadà, ìjọba náà ti lọ ̀dọ̀ arákùnrin mi, nítorí ó ti sọ́dọ̀ rẹ̀ láti ọwọ́ Olúwa . 16 Nísinsin yìí mo ìbéèrè kan láti bi ́, ṣe kọ̀ fún mi."

Ó , "O ."

17 Bẹ́̀ ni ó tẹ̀síwájú , "Mo bẹ̀ ́, jọ̀wọ́ sọ fún Solomoni ọba (òun yóò kọ̀ fún ́) ó fún mi Abiṣagi ará Ṣunemu aya."

18 Batṣeba dáhùn , "Ó dára èmi yóò ọba sọ̀rọ̀ nítorí rẹ̀."

19 Nígbà Batṣeba tọ Solomoni ọba lọ láti a sọ̀rọ̀ nítorí Adonijah, ọba dìde láti pàdé rẹ̀, ó tẹríba fún un, ó jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀. Ó tẹ́ ìtẹ́ kan fún ìyá ọba, ó jókòó lọ́wọ́ ̀tún rẹ̀.

20 Ó , "Mo ìbéèrè kékeré kan láti béèrè lọ́wọ́ rẹ, ṣe kọ̀ fún mi."

Ọba dáhùn , "Béèrè, ìyá mi; èmi yóò kọ̀ ́."

21 Nígbà náà ni ó , "Jẹ́ a fi Abiṣagi ará Ṣunemu fún Adonijah arákùnrin rẹ aya."

22 Solomoni ọba ìyá rẹ̀ lóhùn , "Èéṣe ìwọ fi béèrè Abiṣagi ará Ṣunemu fún Adonijah! Ìwọ ìbá béèrè ìjọba fún un pẹ̀nítorí ̀gbọ́n mi í ṣe, fún òun pàápàá àti fún Abiatari àlùfáà àti fun Joabu ọmọ Seruiah!"

23 Nígbà náà ni Solomoni ọba fi Olúwa búra , "Ọlọ́run ki ó jẹ , àti bẹ́̀ pẹ̀, Adonijah fi ̀rẹ̀ san ìbéèrè yìí! 24 Àti nísinsin yìí, ó ti dájú Olúwa láààyè, ẹni ó ti mi jókòó lórí ìtẹ́ baba mi Dafidi, àti ó ti kọ́ ilé fún mi ó ti ṣèlérí, lónìí ni a ó pa Adonijah!" 25 Solomoni ọba pàṣẹ fún Benaiah ọmọ Jehoiada, ó kọlu Adonijah, ó .

26 Ọba fún Abiatari àlùfáà , "Padà lọ pápá rẹ ni Anatoti, ó yẹ fún láti , ṣùgbọ́n èmi yóò pa ́ nísinsin yìí, nítorí o ti gbé àpótí ̀Olúwa Olódùmarè níwájú Dafidi baba mi, o ti ìpín nínú gbogbo ìyà baba mi jẹ." 27 Bẹ́̀ ni Solomoni yọ Abiatari kúrò nínú iṣẹ́ àlùfáà Olúwa, ó ̀rọ̀ Olúwa ó ti sọ nípa ilé Eli Ṣilo ṣẹ.

28 Nígbà ìròyìn ̀dọ̀ Joabu, ẹni ó ti dìtẹ̀ pẹ̀Adonijah ó tilẹ̀ jẹ́ pẹ̀Absalomu, ó sálọ sínú àgọ́ Olúwa, ó di ìwo pẹpẹ . 29 A sọ fún Solomoni ọba Joabu ti sálọ sínú àgọ́ Olúwa àti ó ̀gbẹ́ pẹpẹ. Nígbà náà ni Solomoni pàṣẹ fún Benaiah ọmọ Jehoiada , "Lọ, o kọlù ú."

30 Benaiah wọ inú àgọ́ Olúwa, ó fún Joabu , "Ọba sọ , Jáde .’ "

Ṣùgbọ́n ó dáhùn , "Bẹ́̀ kọ́, èmi yóò níhìn-ín."

Benaiah èsì fún ọba, "Báyìí ni Joabu ṣe mi lóhùn."

31 Ọba pàṣẹ fún Benaiah , "Ṣe ó ti . Kọlù ú, o sin ín, o ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ mi àti kúrò lọ́dọ̀ ilé baba mi, Joabu ti ta sílẹ̀. 32 Olúwa yóò san ̀jẹ̀ ó ti ta sílẹ̀ padà fún un, nítorí ó kọlu ọkùnrin méjì, ó fi idà rẹ̀ pa wọ́n, Dafidi baba mi mọ̀. Àwọn méjèèjì ni Abneri ọmọ Neri olórí ogun Israẹli, àti Amasa ọmọ Jeteri olórí ogun Juda, wọ́n jẹ́ olódodo, wọ́n sàn ju òun fúnra rẹ̀ lọ. 33 ̀bi ̀jẹ̀ wọn sórí Joabu àti sórí irú-ọmọ rẹ̀ títí láé. Ṣùgbọ́n sórí Dafidi àti irú-ọmọ rẹ̀, ilé rẹ̀ àti ìtẹ́ rẹ̀, ni àlàáfíà Olúwa títí láé."

34 Bẹ́̀ ni Benaiah ọmọ Jehoiada gòkè lọ, ó kọlu Joabu, ó pa á, a sin ín ilẹ̀ ibojì ara rẹ̀ aginjù. 35 Ọba fi Benaiah ọmọ Jehoiada jẹ olórí ogun ipò Joabu àti Sadoku àlùfáà ipò Abiatari.

36 Nígbà náà ni ọba ránṣẹ́ Ṣimei, ó fún un , "Kọ́ ilé fún ara rẹ Jerusalẹmu, o máa gbé ibẹ̀, ṣùgbọ́n o ṣe lọ ibòmíràn. 37 Ọjọ́ ìwọ jáde, o kọjá àfonífojì Kidironi, ìwọ ó mọ̀ dájúdájú ìwọ yóò ; ̀jẹ̀ rẹ yóò lórí ara rẹ."

38 Ṣimei ọba lóhùn , "Ohun ìwọ sọ dára. Ìránṣẹ́ rẹ yóò ṣe olúwa mi ọba ti ." Ṣimei gbé Jerusalẹmu fún ìgbà pípẹ́.

39 Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ọdún mẹ́ta, àwọn ọmọ ̀dọ̀ Ṣimei méjì sálọ sọ́dọ̀ Akiṣi ọmọ Maaka, ọba Gati, a sọ fún Ṣimei , "Àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ méjì Gati." 40 Fún ìdí èyí, ó di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ gàárì, ó lọ sọ́dọ̀ Akiṣi Gati láti àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀. Bẹ́̀ ni Ṣimei lọ, ó àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ padà bọ̀ láti Gati.

41 Nígbà a sọ fún Solomoni Ṣimei ti lọ láti Jerusalẹmu Gati, ó ti padà. 42 Ọba pe Ṣimei lẹ́jọ́, ó fún un , "Ǹjẹ́ èmi ti búra ti Olúwa, èmi ti kìlọ̀ fún , ọjọ́ ìwọ kúrò láti lọ ibikíbi, o mọ̀ dájú ìwọ yóò .Nígbà náà ni ìwọ sọ fún mi , Ohun ìwọ sọ dára. Èmi yóò ṣe ìgbọ́ràn.43 Èéṣe, nígbà náà ìwọ pa ìbúra Olúwa mọ́, àti o ṣe ìgbọ́ràn àṣẹ mo pa fún ?"

44 Ọba tún fún Ṣimei , "Ìwọ mọ̀ ọkàn rẹ gbogbo búburú ìwọ ti ṣe Dafidi baba mi. Báyìí, Olúwa yóò san gbogbo ìṣe búburú rẹ padà fún . 45 Ṣùgbọ́n a ó bùkún fún Solomoni ọba, ìtẹ́ Dafidi yóò láìfòyà níwájú Olúwa títí láéláé."

46 Nígbà náà ni ọba pàṣẹ fún Benaiah ọmọ Jehoiada, ó jáde lọ, ó kọlu Ṣimei, ó pa á.

Ìjọba náà fi ìdí múlẹ̀ ọwọ́ Solomoni.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-