Publicidade

1 Reis 8

A gbé àpótí ̀inú tẹmpili

1 8.1-6: If 11.19. Nígbà náà ni Solomoni pe àwọn àgbàgbà Israẹli àti gbogbo àwọn olórí àwọn ̀àti àwọn olórí ìdílé àwọn ọmọ Israẹli jọ papọ̀, níwájú Solomoni ọba Jerusalẹmu, láti gbé àpótí ̀Olúwa láti ìlú Dafidi, ń ṣe Sioni. 2 Gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli pe ara wọn jọ sọ́dọ̀ Solomoni ọba àkókò àjọ ọdún oṣù Etanimu í ṣe oṣù keje.

3 Nígbà gbogbo àwọn àgbàgbà Israẹli , àwọn àlùfáà gbé àpótí ̀, 4 wọ́n gbé àpótí ̀Olúwa àti àgọ́ àjọ ènìyàn àti gbogbo ohun èlò mímọ́ ó nínú àgọ́. Àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi gbé wọn gòkè , 5 àti Solomoni ọba, àti gbogbo ìjọ ènìyàn ó péjọ ̀dọ̀ rẹ̀ pẹ̀rẹ̀ níwájú àpótí ̀, wọ́n ń fi ̀pọ̀lọpọ̀ àgùntàn àti màlúù a le mọ iye, àti a le ẹbọ.

6 Nígbà náà ni àwọn àlùfáà gbé àpótí ̀ti májẹ̀Olúwa ipò rẹ̀, ibi inú lọ́hùn ún ilé Olúwa, Ibi Mímọ́ Jùlọ, wọ́n gbé e abẹ́ ìyẹ́ àwọn kérúbù. 7 Àwọn kérúbù na ìyẹ́ wọn méjèèjì ibi àpótí ̀, wọ́n bo àpótí ̀náà, àti àwọn ̀rẹ̀ a fi ń gbé e. 8 Àwọn ̀yìí ga bẹ́̀ a fi le orí wọn láti Ibi Mímọ́ níwájú ibi a mímọ́, ṣùgbọ́n a wọn lóde Ibi Mímọ́, wọ́n níbẹ̀ títí di òní yìí. 9 ohun kankan nínú àpótí ̀ṣe wàláà òkúta méjì Mose ti fi ibẹ̀ Horebu, níbi Olúwa ti àwọn ọmọ Israẹli májẹ̀, lẹ́yìn ìgbà wọ́n jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti.

10 8.10,11: 2Ki 5.13,14; If 15.8. Nígbà àwọn àlùfáà jáde láti Ibi Mímọ́, àwọsánmọ̀ kún ilé Olúwa. 11 Àwọn àlùfáà le ṣiṣẹ́ wọn nítorí àwọsánmọ̀ náà, nítorí ògo Olúwa kún ilé náà.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-