Publicidade

1 Samuel 15

Olúwa kọ Saulu ọba

1 Samuẹli fún Saulu , "Èmi ni Olúwa rán láti fi àmì òróró yàn ́ ọba lórí àwọn ènìyàn rẹ̀ Israẹli; fetísílẹ̀ láti gbọ́ iṣẹ́ Olúwa rán mi ́. 2 Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun , Èmi yóò jẹ àwọn Amaleki fún ohun wọ́n ti ṣe Israẹli nígbà wọn wọn lọ́nígbà wọn ń bọ̀ láti Ejibiti. 3 Lọ nísinsin yìí, o kọlu Amaleki, o pa gbogbo ohun ó jẹ́ tiwọn à parun. ṣe wọn , pa ọkùnrin àti obìnrin wọn, ọmọ kékeré àti ọmọ ọmú, màlúù àti àgùntàn, ìbákasẹ àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn.’ "

4 Bẹ́̀ ni Saulu àwọn ènìyàn jọ, ó ka iye wọn Talaemu, wọ́n jẹ́ ogún ̀kẹ́ (200,000) àwọn ológun ẹlẹ́ṣẹ̀, pẹ̀ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) àwọn ọkùnrin Juda. 5 Saulu lọ ìlú Amaleki ó gọ wọ́n àfonífojì kan. 6 Nígbà náà ni ó fún àwọn ará Keni , "lọ, kúrò Amaleki èmi ba à run yín pẹ̀wọn; nítorí ̀yin fi àánú hàn fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli nígbà wọ́n gòkè ti Ejibiti ." Bẹ́̀ ni àwọn Kenaiti lọ kúrò láàrín àwọn Amaleki.

7 Nígbà náà ni Saulu kọlu àwọn Amaleki láti Hafila Ṣuri, ó fi ìlà-oòrùn Ejibiti. 8 Ó Agagi ọba Amaleki láààyè, ó fi idà rẹ̀ kọlù gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀. 9 Ṣùgbọ́n Saulu àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ Agagi àti èyí ó dára jùlọ nínú àgùntàn àti màlúù àti ̀dọ́-àgùntàn àbọ́pa àti gbogbo nǹkan dára. Wọ́n fẹ́ pa àwọn wọ̀nyí run pátápátá ṣùgbọ́n gbogbo nǹkan dára níláárí ni wọ́n parun pátápátá.

10 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ Samuẹli , 11 "Èmi káàánú gidigidi mo fi Saulu jẹ ọba, nítorí ó ti yípadà kúrò lẹ́yìn mi, pa ̀rọ̀ mi mọ́." Inú Samuẹli bàjẹ́ gidigidi, ó pe Olúwa gbogbo òru náà.

12 òwúrọ̀ kùtùkùtù Samuẹli dìde láti lọ pàdé Saulu, ṣùgbọ́n wọ́n sọ fún un , "Saulu ti Karmeli. Ó ti kọ́ ibìkan fún ara rẹ̀ níbẹ̀, ó ti yípadà, ó ti sọ̀kalẹ̀ lọ Gilgali."

13 Nígbà Samuẹli ̀dọ̀ rẹ̀, Saulu fún un , "Olúwa bùkún fún , mo ti ṣe ohun Olúwa pàṣẹ."

14 Ṣùgbọ́n Samuẹli , "Èwo ni igbe àgùntàn mo ń gbọ́ etí mi? ni igbe màlúù ti mo ń gbọ́ yìí?"

15 Saulu dáhùn , "Àwọn ọmọ-ogun o wọn láti Amaleki , wọ́n àwọn àgùntàn, àti màlúù ó dára jùlọ láti fi ẹbọ Olúwa Ọlọ́run rẹ, ṣùgbọ́n a pa àwọn tókù run pátápátá."

16 Samuẹli fún Saulu , "Dákẹ́ , jẹ́ èmi ó sọ ohun Olúwa fún mi alẹ́ àná fún ."

Saulu , "Sọ fún mi."

17 Samuẹli , "ó tilẹ̀ jẹ́ ìwọ fi ìgbà kan kéré lójú ara rẹ, ǹjẹ́ ìwọ ha di olórí ̀Israẹli? Olúwa fi àmì òróró yàn ́ ọba lórí Israẹli. 18 Olúwa rán níṣẹ́ , Lọ, o pa àwọn ènìyàn búburú ará Amaleki run pátápátá; gbóguntì wọ́n títí ìwọ yóò fi run wọ́n.19 Èéṣe ìwọ fi gbọ́ ti Olúwa? Èéṣe ìwọ fi sáré ìkógun o ṣe búburú níwájú Olúwa?"

20 Saulu fún Samuẹli , "Ṣùgbọ́n èmi ti ṣe ìgbọ́ràn Olúwa, èmi ti lọ ̀Olúwa rán mi. Mo ti pa àwọn ará Amaleki run pátápátá, mo ti Agagi ọba wọn padà . 21 Àwọn ọmọ-ogun ti àgùntàn àti màlúù lára ìkógun èyí ó dára láti fi fún Olúwa láti fi ẹbọ Olúwa Ọlọ́run rẹ Gilgali."

22 15.22: Mk 12.33. Ṣùgbọ́n Samuẹli dáhùn ,

"Olúwa ha inú dídùn ẹbọ sísun àti ẹbọ

ju a gba ohùn Olúwa gbọ́?

Ìgbọ́ràn sàn ju ẹbọ lọ,

ìfetísílẹ̀ sàn ju ̀àgbò lọ.

23 Nítorí ìṣọ̀tẹ̀ dàbí ̀ṣẹ̀ àfọ̀ṣẹ,

àti ìgbéraga ̀ṣẹ̀ ìbọ̀rìṣà.

Nítorí ìwọ ti kọ ̀rọ̀ Olúwa,

Òun ti kọ̀ ́ ọba."

24 Nígbà náà ni Saulu fún Samuẹli , "Èmi ti ṣẹ̀. Mo ti òfin Olúwa àti ̀rọ̀ rẹ̀. Èmi bẹ̀àwọn ènìyàn bẹ́̀ ni èmi gba ohùn wọn gbọ́. 25 Mo bẹ̀ ́ nísinsin yìí, dárí ̀ṣẹ̀ mi , ó yípadà pẹ̀mi, èmi ó sin Olúwa."

26 Ṣùgbọ́n Samuẹli fún un , "Èmi padà. Ìwọ ti kọ ̀rọ̀ Olúwa sílẹ̀, Olúwa ti kọ̀ ́ ọba lórí Israẹli!"

27 Samuẹli ti fẹ́ yípadà láti lọ, Saulu di ̀ìlekè rẹ̀ , ó fàya; 28 Samuẹli fún un , "Olúwa ti fa ìjọba Israẹli ya kúrò lọ́wọ́ ̀ rẹ lónìí, ó ti fi fún aládùúgbò rẹ kan ó sàn ́ lọ. 29 Ẹni ó ń ṣe ògo Israẹli, í purọ́, bẹ́̀ ni í ọkàn rẹ̀ padà; nítorí í ṣe ènìyàn yóò ọkàn rẹ̀ padà."

30 Saulu , "Èmi ti ṣẹ̀, ṣùgbọ́n jọ̀wọ́ bu ọlá fún mi níwájú àwọn àgbàgbà ènìyàn mi, àti níwájú u Israẹli, yípadà pẹ̀mi, èmi ó tẹríba fún Olúwa Ọlọ́run rẹ." 31 Bẹ́̀ ni Samuẹli yípadà pẹ̀Saulu, Saulu sin Olúwa.

32 Nígbà náà ni Samuẹli , "Agagi ọba àwọn ará Amaleki fún mi."

Agagi tọ̀ ́ ìgboyà pẹ̀èrò , "Nítòótọ́ ìkorò ikú ti kọjá."

33 Ṣùgbọ́n Samuẹli ,

"idà rẹ ti sọ àwọn obìnrin di aláìní ọmọ

bẹ́̀ ni ìyá rẹ yóò di aláìní ọmọ láàrín obìnrin."

Samuẹli pa Agagi níwájú Olúwa ni Gilgali.

34 Nígbà náà ni Samuẹli lọ Rama, Saulu gòkè lọ ilé e rẹ̀ Gibeah Saulu. 35 Samuẹli padà mọ́ láti wo Saulu títí ó fi di ọjọ́ ikú u rẹ̀, ṣùgbọ́n Samuẹli káàánú fún Saulu. Ó dun Olúwa ó fi Saulu jẹ ọba lórí Israẹli.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-