Publicidade

1 Samuel 20

Dafidi àti Jonatani

1 Nígbà náà ni Dafidi kúrò Naioti ti Rama ó lọ sọ́dọ̀ Jonatani ó béèrè , "ni mo ṣe? ni ̀ṣẹ̀ mi? Báwo ni mo ṣe ṣẹ baba rẹ, ó ń ̀láti gba ̀mi?"

2 Jonatani dáhùn , "a i! Ìwọ ! ó baba mi í ṣe ohunkóhun ó tóbi tàbí ó kéré, láìfi lọ̀ . Èéṣe yóò fi fi èyí pamọ́ fún mi? bẹ́̀."

3 Ṣùgbọ́n Dafidi tún búra, ó , "Baba rẹ mọ̀ dáradára mo ojúrere ojú rẹ, ó fún ara rẹ̀ , Jonatani gbọdọ̀ mọ èyí yóò á nínú jẹ́.’ Síbẹ̀ nítòótọ́ Olúwa ti láààyè àti gẹ́gẹ́ ìwọ ti láààyè, ìgbésẹ̀ kan ni ó láàrín ìyè àti ikú."

4 Jonatani fún Dafidi , "Ohunkóhun ìwọ ń fẹ́ èmi ó ṣe, èmi yóò ṣe é fún ."

5 Dafidi fún Jonatani , "ó, ̀la ni oṣù tuntun, mo gbọdọ̀ ọba jẹun, ṣùgbọ́n jẹ́ èmi ó lọ láti fi ara pamọ́ lórí pápá títí di àṣálẹ́ ọjọ́ kẹta. 6 ó ṣe baba rẹ fẹ́ mi , o fún un , Dafidi fi tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀ béèrè ààyè láti sáré lọ Bẹtilẹhẹmu ìlú rẹ̀ nítorí wọ́n ń ṣe ẹbọ ọdọọdún ibẹ̀ fún gbogbo ìdílé rẹ̀.’ 7 o , Àlàáfíà ni,nígbà náà, ìránṣẹ́ rẹ láìléwu. Ṣùgbọ́n ó bínú gidigidi, ìwọ yóò mọ̀ dájú ó pinnu láti ṣe ìpalára mi. 8 Ṣùgbọ́n tìrẹ ìwọ, fi ojúrere wo ìránṣẹ́ rẹ; nítorí ìwọ ti a májẹ̀pẹ̀rẹ níwájú Olúwa. mo jẹ̀bi, pa fún ara rẹ! Èéṣe ìwọ yóò fi fi baba rẹ lọ́wọ́?"

9 Jonatani , "a i! Ti mo ti gbọ́ baba mi ti pinnu láti pa ́ lára, ṣé èmi sọ fún ?"

10 Nígbà náà ni Dafidi fún Jonatani , "Ta ni yóò sọ fún mi baba rẹ̀ lóhùn ohùn líle?"

11 Jonatani fún Dafidi , ", jẹ́ a jáde lọ sórí pápá." Nígbà náà wọ́n jáde lọ.

12 Nígbà náà ni Jonatani fún Dafidi , "Mo fi Olúwa Ọlọ́run àwọn Israẹli búra , èmi yóò i dájú mo gbọ́ ti ẹnu baba mi ìwòyí ̀la tàbí ̀túnla! ó inú dídùn , èmi yóò ránṣẹ́ , èmi yóò jẹ́ o mọ̀? 13 Ṣùgbọ́n baba mi fẹ́ pa ́ lára, Olúwa ó ṣe bẹ́̀ àti bẹ́̀ lọ Jonatani; èmi jẹ́ o mọ̀, n jẹ́ o lọ àlàáfíà. Olúwa ó pẹ̀rẹ gẹ́gẹ́ ó ti pẹ̀baba mi. 14 Ṣùgbọ́n fi àìkùnà inú rere hàn inú rere Olúwa, níwọ́n ìgbà mo láààyè wọ́n ba à pa . 15 ṣe àánú rẹ kúrò lórí ìdílé mi títí láé. Olúwa tilẹ̀ gbogbo ̀Dafidi kúrò lórí ilẹ̀."

16 Nígbà náà ni Jonatani ilé Dafidi májẹ̀, "Olúwa yóò pe àwọn àti Dafidi láti ṣírò." 17 Jonatani Dafidi tún ìbúra ṣe nítorí ìfẹ́ ó i, nítorí ó fẹ́ gẹ́gẹ́ ó ti fẹ́ràn ara rẹ̀.

18 Nígbà náà ni Jonatani fún Dafidi , "Lọ́la ibi àsè ìbẹ̀rẹ̀ oṣù tuntun, a yóò fẹ́ , nítorí ààyè rẹ yóò ṣófo. 19 ̀túnla lọ́wọ́ alẹ́ lọ ibi o pamọ́ nígbà ìṣòro yìí bẹ̀rẹ̀, o dúró níbi òkúta Eselu. 20 Èmi yóò ta ọfà mẹ́ta ̀gbẹ́ ibẹ̀, gẹ́gẹ́ i mo ta á àmì ibìkan. 21 Èmi yóò rán ọmọdékùnrin kan èmi yóò fún un , Lọ, o lọ ọfà náà.mo sọ fún un , ó, ọfà wọ̀nyí ibi báyìí ̀gbẹ́ ̀ rẹ; wọn síbí,o , nítorí , gẹ́gẹ́ Olúwa ti ààyè, o àlàáfíà; ewu. 22 Ṣùgbọ́n mo sọ fún ọmọdékùnrin náà , ó, àwọn ọfà náà ń bẹ níwájú rẹ,ǹjẹ́ máa tìrẹ lọ, nítorí Olúwa ni ó rán lọ. 23 Nípa ̀rọ̀ èmi àti ìwọ jọ sọ, rántí Olúwa jẹ́ ẹlẹ́rìí láàrín ìwọ àti èmi títí láéláé."

24 Bẹ́̀ ni Dafidi pamọ́ sínú pápá. Nígbà àsè ìbẹ̀rẹ̀ oṣù tuntun , ọba jókòó láti jẹun. 25 Ọba jókòó gẹ́gẹ́ ipò o rẹ̀ ibi ó máa ń jókòó lórí ìjókòó ó lẹ́gbẹ̀́ ògiri, òdìkejì Jonatani, Abneri jókòó ti Saulu, ṣùgbọ́n ààyè Dafidi ṣófo. 26 Saulu sọ nǹkan kan ọjọ́ náà, nítorí ó , "Nǹkan kan ti ṣẹlẹ̀ Dafidi láti jẹ́ ó di aláìmọ́ lóòtítọ́ ó jẹ́ aláìmọ́." 27 Ṣùgbọ́n ọjọ́ kejì, ọjọ́ kejì oṣù, ààyè Dafidi tún ṣófo. Nígbà náà ni Saulu fún ọmọ rẹ̀ Jonatani , "ni ó ọmọ Jese fi ibi oúnjẹ, lánàá àti lónìí?"

28 Jonatani dáhùn , "Dafidi bẹ̀ tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀ fún ààyè láti lọ Bẹtilẹhẹmu. 29 Ó , Jẹ́ n lọ, nítorí ìdílé wa ń ṣe ìrúbọ ìlú, àwọn ̀gbọ́n ̀n mi ti pàṣẹ fún mi láti níbẹ̀; èmi ojúrere ojú rẹ, jẹ́ n lọ láti lọ àwọn ̀gbọ́n mi.Ìdí nìyìí fi orí tábìlì oúnjẹ ọba."

30 Ìbínú Saulu ru Jonatani ó fún un , "Ìwọ ọmọ aláìgbọ́ràn àti ọlọ̀tẹ̀ búburú yìí, ṣé èmi ti mọ̀ , ìwọ ti yan ọmọ Jese fún ìtìjú ti ara rẹ àti fún ìtìjú màmá rẹ ó ? 31 Níwọ́n ìgbà ọmọ Jese láààyè lórí ilẹ̀ ayé, a yóò fi ẹsẹ̀ ìwọ tàbí ti ìjọba rẹ múlẹ̀. Nísinsin yìí ránṣẹ́ o lọ un fún mi, nítorí ó gbọdọ̀ !"

32 Jonatani béèrè lọ́wọ́ baba rẹ̀ , "Èéṣe àwa yóò fi pa á? ni ó ṣe?" 33 Ṣùgbọ́n Saulu ju ̀kọ̀ rẹ̀ Jonatani láti gún un pa. Nígbà náà ni Jonatani mọ̀ baba rẹ̀ mọ̀ ́n mọ̀ fẹ́ pa Dafidi ni.

34 Bẹ́̀ ni Jonatani fi ìbínú dìde kúrò ni ibi oúnjẹ, jẹun ni ọjọ́ kejì oṣù náà, inú rẹ̀ bàjẹ́ gidigidi fún Dafidi, nítorí baba rẹ̀ dójútì í.

Jonatani kìlọ̀ fún Dafidi

35 Ó ṣe, òwúrọ̀ ni Jonatani jáde lọ oko àkókò òun àti Dafidi ti fi àdéhùn , ọmọdékùnrin kan pẹ̀rẹ̀. 36 Ó si fún ọmọdékùnrin rẹ̀ , "Sáré, o si àwọn ọfà èmi ó ta." ọmọdé náà ti ń sáré, òun tafà rékọjá rẹ̀. 37 Nígbà ọmọdékùnrin náà ibi ọfà Jonatani ta, Jonatani kọ ọmọdékùnrin náà ó , "Ọfà náà ha níwájú rẹ bi?" 38 Jonatani kọ ọmọdékùnrin náà , "Sáré! Yára! ṣe dúró!" Ọmọdékùnrin Jonatani ṣa àwọn ọfà náà, ó tọ olúwa rẹ̀ . 39 (Ọmọdékùnrin náà mọ̀ nǹkan; ṣùgbọ́n Jonatani àti Dafidi ni ó mọ ̀ràn náà.) 40 Jonatani fi apó àti ọrun rẹ̀ fún ọmọdékùnrin rẹ̀, ó fún un , "Lọ, o wọn lọ ìlú."

41 ọmọdékùnrin náà ti lọ tán, Dafidi dìde láti ibi ìhà gúúsù òkúta náà, ó wólẹ̀, ó tẹríba ìdojúbolẹ̀ lẹ́̀mẹ́ta fún Jonatani, wọ́n fi ẹnu ko ara wọn lẹ́nu, wọ́n jùmọ̀ sọkún, èkínní pẹ̀èkejì rẹ̀, ṣùgbọ́n Dafidi sọkún púpọ̀ .

42 Jonatani fún Dafidi , "Máa lọ àlàáfíà, o ti jẹ́ àwa méjèèjì jùmọ̀ búra ni orúkọ Olúwa , Ki Olúwa ó láàrín èmi àti ìwọ, láàrín irú-ọmọ mi àti láàrín irú-ọmọ rẹ̀ láéláé.’ " Òun dìde, ó lọ kúrò: Jonatani lọ ìlú.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-