Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuel 12

Natani Dafidi

1 Olúwa rán Natani Dafidi òun tọ̀ ́ , ó fún un , "Ọkùnrin méjì ń bẹ ìlú kan; ̀kan jẹ́ ọlọ́rọ̀, èkejì jẹ́ tálákà. 2 Ọkùnrin ọlọ́rọ̀ náà àgùntàn àti màlúù lọ́pọ̀lọ́pọ̀. 3 Ṣùgbọ́n ọkùnrin tálákà náà nǹkan ṣe àgùntàn kékeré kan èyí ó ń tọ́, ó dàgbà ọwọ́ rẹ̀ pẹ̀àwọn ọmọ rẹ̀; a máa jẹ nínú oúnjẹ rẹ̀, a máa mu nínú ago rẹ̀, a máa dùbúlẹ̀ àyà rẹ̀, ó dàbí ọmọbìnrin kan fún un.

4 "Àlejò kan tọ ọkùnrin ọlọ́rọ̀ náà , òun fẹ́ nínú àgùntàn rẹ̀, àti nínú màlúù rẹ̀, láti fi ṣe àlejò fún ẹni ó tọ̀ ́ , o àgùntàn ọkùnrin tálákà náà fi ṣe àlejò fún ọkùnrin ó tọ̀ ́ ."

5 Ìbínú Dafidi ru gidigidi ọkùnrin náà; ó fún Natani , "Olúwa ti ń bẹ láààyè, ọkùnrin náà ó ṣe nǹkan yìí, kíkú ni yóò . 6 Òun yóò san àgùntàn náà padà mẹ́rin mẹ́rin, nítorí ó ṣe nǹkan yìí àti nítorí àánú."

7 Natani fún Dafidi , "Ìwọ ni ọkùnrin náà. Báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli , Èmi fi ́ jẹ ọba lórí Israẹli, èmi gbà ́ lọ́wọ́ Saulu. 8 Èmi fi ilé olúwa rẹ fún , àti àwọn obìnrin olúwa rẹ àyà rẹ, èmi fi ìdílé Israẹli àti ti Juda fún ; àwọn wọ̀nyí kéré fún èmi ìbá fún i bẹ́̀ lọ. 9 Èéṣe ìwọ fi kẹ́gàn ̀rọ̀ Olúwa, ìwọ fi ṣe nǹkan ó burú lójú rẹ̀, àní ìwọ fi fi idà pa Uriah ará Hiti, àti ìwọ fi obìnrin rẹ̀ láti fi ṣe obìnrin rẹ, o fi idà àwọn ọmọ Ammoni pa á. 10 Ǹjẹ́ nítorí náà idà yóò kúrò ilé rẹ títí láé; nítorí ìwọ gàn , ìwọ aya Uriah ará Hiti láti ṣe aya rẹ.

11 "Báyìí ni Olúwa , kíyèsi i, Èmi ó jẹ́ ibi ó dìde láti inú ilé rẹ , èmi ó gba àwọn obìnrin rẹ lójú rẹ, èmi ó fi wọ́n fún aládùúgbò rẹ, òun ó àwọn obìnrin rẹ sùn níwájú òòrùn yìí. 12 Àti ìwọ ṣe é ìkọ̀kọ̀, ṣùgbọ́n èmi ó ṣe nǹkan yìí níwájú gbogbo Israẹli, àti níwájú òòrùn.’ "

13 Dafidi fún Natani , "Èmi ṣẹ̀ Olúwa!"

Natani fún Dafidi , "Olúwa pẹ̀ti ̀ṣẹ̀ rẹ kúrò; ìwọ yóò . 14 Ṣùgbọ́n nítorí nípa ìwà yìí, ìwọ fi ààyè sílẹ̀ fún àwọn ̀Olúwa láti sọ ̀rọ̀-òdì, ọmọ náà a ó fún , kíkú yóò ."

Ọmọ náà

15 Natani lọ ilé rẹ̀ Olúwa fi ààrùn kọlu ọmọ náà obìnrin Uriah fún Dafidi, ó ṣe àìsàn púpọ̀. 16 Dafidi bẹ Ọlọ́run nítorí ọmọ náà, Dafidi gbààwẹ̀, ó wọ inú ilé lọ, ó dùbúlẹ̀ lórí ilé ni òru náà. 17 Àwọn àgbàgbà ilé rẹ̀ dìde tọ̀ ́ lọ, láti gbé e dìde lórí ilé, ó kọ̀, wọn jẹun.

18 ọjọ́ keje, ọmọ náà . Àwọn ìránṣẹ́ Dafidi bẹ̀láti fún un , ọmọ náà : nítorí wọ́n , "Kíyèsi i, nígbà ọmọ náà ń bẹ láààyè, àwa sọ̀rọ̀ fún un, òun kọ̀ si gbọ́ ohùn wa! Ǹjẹ́ yóò ti ṣe ara rẹ̀ èṣe , àwa fún un , ọmọ náà ."

19 Nígbà Dafidi àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ń sọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́, Dafidi kíyèsi i, ọmọ náà , Dafidi béèrè lọ́wọ́ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ , "Ọmọ náà ?"

Wọ́n a lóhùn , "Ó ."

20 Dafidi dìde ilẹ̀, ó wẹ̀, ó fi òróró pa ara, ó pààrọ̀ aṣọ rẹ̀, ó wọ inú ilé Olúwa lọ, ó wólẹ̀ sin, ó ilé rẹ̀ ó béèrè, wọ́n gbé oúnjẹ kalẹ̀ níwájú rẹ̀, ó jẹun.

21 Àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ léèrè , "ni èyí ìwọ ṣe yìí? Nítorí ọmọ náà nígbà ó ń bẹ láààyè ìwọ gbààwẹ̀, o sọkún; ṣùgbọ́n nígbà ọmọ náà , ó dìde ó jẹun."

22 Ó , "Nígbà ọmọ náà ń bẹ láààyè, èmi gbààwẹ̀, èmi sọkún: nítorí èmi , Ta ni ó mọ̀? Olúwa ó ṣàánú mi, ọmọ náà le .23 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ó ti , nítorí kín ni èmi ó ṣe máa gbààwẹ̀? Èmi ha tún un padà ? Èmi ni yóò tọ̀ ́ lọ, òun yóò tún tọ̀ ."

Batṣeba tún ọmọ mìíràn a Solomoni

24 Dafidi ṣìpẹ̀ fún Batṣeba aya rẹ̀, ó wọlé tọ̀ ́, ó a dàpọ̀, òun ọmọkùnrin kan, Dafidi sọ orúkọ rẹ̀ Solomoni, Olúwa fẹ́ . 25 Ó rán Natani wòlíì, ó pe orúkọ rẹ̀ Jedidiah, nítorí Olúwa.

Ìṣẹ́gun Dafidi lórí àwọn Ammoni

26 12.26-31: 1Ki 20.1-3. Joabu Rabba ti àwọn ọmọ Ammoni jagun, ó gba ìlú ọba wọn. 27 Joabu rán àwọn ìránṣẹ́ Dafidi, ó , "Èmi ti Rabba , èmi ti gba àwọn ìlú olómi. 28 Ǹjẹ́ nítorí náà àwọn ènìyàn ìyókù jọ, o ti ìlú náà, o gbà á, èmi à gba ìlú náà a ba à é orúkọ mi."

29 Dafidi gbogbo ènìyàn náà jọ, Rabba, ó a , ó gbà á. 30 Òun gba adé ọba wọn kúrò lórí rẹ̀, ìwúwo rẹ̀ jẹ́ tálẹ́ǹtì wúrà kan, ó òkúta oníyebíye lára rẹ̀; a fi Dafidi lórí. Òun ìkógun ìlú náà ni ̀pọ̀lọpọ̀. 31 Ó àwọn ènìyàn náà ó nínú rẹ̀, ó fi wọ́n iṣẹ́ ayùn, àti iṣẹ́ nǹkan ìtulẹ̀ a fi irin ṣe, àti iṣẹ́ àáké irin, ó fi wọ́n iṣẹ́ bíríkì ṣíṣe, bẹ́̀ náà ni òun ṣe gbogbo ìlú àwọn ọmọ Ammoni. Dafidi àti gbogbo àwọn ènìyàn náà padà Jerusalẹmu.

Veja também