Publicidade

Deuteronômio 13

sin àwọn ọlọ́run mìíràn

1 wòlíì tàbí alásọtẹ́lẹ̀ nípa àlá lílá farahàn láàrín yín, ó ń kéde iṣẹ́ àmì tàbí iṣẹ́ ìyanu, 2 iṣẹ́ àmì tàbí iṣẹ́ ìyanu ó sọ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ òun , "jẹ́ a tẹ̀ọlọ́run mìíràn" (àwọn ọlọ́run mọ̀ ) "jẹ́ a máa sìn wọ́n," 3 fetí ̀rọ̀ wòlíì tàbí àlá náà, Olúwa Ọlọ́run yín ń dán an yín ni, láti mọ̀ bóyá fẹ́ràn rẹ̀ pẹ̀gbogbo àyà yín àti gbogbo ọkàn an yín. 4 Olúwa Ọlọ́run yín ni tẹ̀, Òun ni bu ọlá fún, pa òfin rẹ̀ mọ́ gbọ́ tirẹ̀, sìn ín, dìímú ṣinṣin. 5 Wòlíì náà tàbí alálàá náà ni pa, nítorí wàásù ìṣọ̀tẹ̀ Olúwa Ọlọ́run yín, ó yín jáde láti Ejibiti , ó yín padà lóko ẹrú. Ó ti gbìyànjú láti yín kúrò lójú ̀Olúwa Ọlọ́run yín ti pàṣẹ fún un yín láti máa rìn. gbọdọ̀ yọ ibi náà kúrò láàrín yín.

6 arákùnrin tìrẹ gan an ọmọ ìyá rẹ tàbí ọmọ rẹ ọkùnrin tàbí obìnrin, aya o fẹ́ràn , tàbí ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ tàn ́ jẹ níkọ̀kọ̀ , "Jẹ́ a lọ sin ọlọ́run mìíràn" (ọlọ́run ìwọ tàbí baba rẹ mọ̀, 7 ọlọ́run àwọn ó láyìíká yín, yálà wọ́n jìnnà tàbí wọ́n nítòsí, láti òpin ilẹ̀ kan òmíràn), 8 ṣe fetí i, i, ṣe dáàbò ó. 9 Ṣùgbọ́n pípa ni o pa á. Ọwọ́ rẹ ni yóò kọ́kọ́ lára rẹ̀ láti pa á, lẹ́yìn náà ọwọ́ gbogbo ènìyàn. 10 Sọ ́ òkúta pa nítorí ó gbìyànjú láti ́ kúrò lẹ́yìn Olúwa Ọlọ́run rẹ, ó jáde ti Ejibiti kúrò oko ẹrú. 11 Gbogbo Israẹli yóò gbọ́, ̀yóò wọ́n, ẹnikẹ́ni nínú yín yóò dán irú ibi bẹ́̀ mọ́.

12 ̀yin gbọ́ a sọ nípa èyíkéyìí nínú àwọn ìlú u yín Olúwa Ọlọ́run yín fún un yín láti máa gbé, 13 àwọn ènìyàn búburú, ti farahàn láàrín yín, ó ti àwọn ènìyàn ìlú wọn ṣìnà lọ, wọ́n , "jẹ́ a lọ sin ọlọ́run mìíràn." (àwọn ọlọ́run mọ̀.) 14 wádìí, béèrè, tọpinpin ̀rọ̀ náà dájúṣáká, ó jẹ́ òtítọ́ ni, ó hàn dájú ìwà ìríra yìí ti ṣẹlẹ̀ láàrín yín. 15 Gbogbo àwọn ó ń gbé ìlú náà ni fi idà run pátápátá. run ún pátápátá, àti ènìyàn àti ẹran ̀sìn inú rẹ̀. 16 gbogbo ìkógun ìlú náà, àárín gbogbo ènìyàn, sun ìlú náà àti gbogbo ìkógun rẹ̀, gẹ́gẹ́ ẹbọ sísun Olúwa Ọlọ́run rẹ. Ó gbọdọ̀ píparun láéláé, ẹnikẹ́ni gbọdọ̀ tún un kọ. 17 A gbọdọ̀ ̀kan nínú àwọn ohun ìyàsọ́tọ̀ fún ìparun wọ̀n-ọn-nì lọ́wọ́ yín, Olúwa ba à le yípadà kúrò nínú ìbínú gbígbóná rẹ̀, yóò ṣàánú fún un yín, yóò a yín kẹ́dùn, yóò pọ̀ i, ó ti búra ṣèlérí fún àwọn baba ńlá yín. 18 Nítorí ̀yin gbọ́rọ̀ Olúwa Ọlọ́run yín, ̀yin ń pa òfin rẹ̀ mọ́, mo ń fún un yín lónìí yìí, ̀yin ń ṣe ohun ó tọ́ lójú rẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-