Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronômio 22

1 22.1-4: El 23.4,5. o màlúù tàbí àgùntàn arákùnrin rẹ ó ń sọnù, ṣe ṣé àìkíyèsí i rẹ̀ ṣùgbọ́n i dájú o padà fún un. 2 ọkùnrin náà í gbé tòsí rẹ tàbí o mọ ẹni náà, un lọ ilé pẹ̀rẹ o fi pamọ́ títí yóò fi a . Nígbà náà ni o fi fún un. 3 Ṣe bákan náà o kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ arákùnrin rẹ tàbí aṣọ ìlekè tàbí ohunkóhun rẹ̀ ó sọnù. ṣe ṣe àìkíyèsí i rẹ̀.

4 o kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tàbí màlúù arákùnrin rẹ o dùbúlẹ̀ sójú ̀, ṣe ṣàìfiyèsí i rẹ̀, ràn án lọ́wọ́ láti dìde dúró lórí ẹsẹ̀ rẹ̀.

5 Obìnrin gbọdọ̀ wọ aṣọ ọkùnrin, tàbí ọkùnrin wọ aṣọ obìnrin, nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ kórìíra ẹnikẹ́ni ó ṣe èyí.

6 ìwọ ṣe alábòápàdé ìtẹ́ ẹyẹ lẹ́gbẹ̀́ ̀, bóyá lára igi tàbí lórí ilẹ̀, ìyá wọn jókòó lórí àwọn ọmọ, tàbí lórí àwọn ẹyin, ṣe gbé ìyá pẹ̀àwọn ọmọ. 7 Ìwọ gbé ọmọ, ṣùgbọ́n i dájú o jọ̀wọ́ ìyá lọ́wọ́ lọ, ó ba à dára fún àti o ̀gígùn.

8 Nígbà o kọ́ ilé tuntun, mọ odi òrùlé rẹ̀ nítorí o ba à ̀bi ìtàjẹ̀ sílẹ̀ sórí ilẹ̀ rẹ ẹnikẹ́ni ṣubú láti òrùlé.

9 22.9-11: Le 19.19. ṣe gbin oríṣìí èso méjì sínú ọgbà àjàrà rẹ; o ṣe bẹ́̀, í ṣe èso oko o gbìn nìkan ṣùgbọ́n èso ọgbà àjàrà pẹ̀yóò bàjẹ́.

10 Ìwọ gbọdọ̀ fi akọ màlúù àti akọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tulẹ̀ pọ̀.

11 Ìwọ gbọdọ̀ wọ aṣọ onírun àgùntàn àti aṣọ funfun papọ̀.

12 22.12: Nu 15.37-41. o ṣe wajawaja etí igun mẹ́rẹ̀̀rin aṣọ ìlekè rẹ.

Ìrúfin ìgbéyàwó

13 ọkùnrin kan ìyàwó àti, lẹ́yìn ìgbà ó ti dùbúlẹ̀ pẹ̀rẹ̀, kórìíra rẹ̀, 14 ó ṣì sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ i, o fún un orúkọ búburú, , "Mo fẹ́ obìnrin yìí, ṣùgbọ́n nígbà mo súnmọ́ ọn. Èmi àmì ìbálé rẹ̀." 15 Nígbà náà ni baba ọmọbìnrin náà àti ìyá rẹ̀ yóò ̀, ó ti ìbálé tẹ́lẹ̀ ̀dọ̀ àwọn àgbàgbà ìlú ẹnu-bodè. 16 Baba obìnrin náà yóò fún àwọn àgbàgbà , "Mo fi ọmọbìnrin mi fún ọkùnrin yìí láti fẹ́ níyàwó, ṣùgbọ́n ó kórìíra rẹ̀. 17 ìsinsin yìí ó ti sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ i ó , Èmi ọmọbìnrin rẹ ó wúńdíá.Ṣùgbọ́n níhìn-ín yìí ni ̀ìbálé ọmọbìnrin mi." Nígbà náà ni àwọn òbí rẹ̀ yóò fi aṣọ hàn níwájú àwọn àgbàgbà ìlú, 18 àwọn àgbàgbà yóò ọkùnrin náà, wọn yóò jẹ . 19 Wọn yóò gba ìtánràn ọgọ́rùn-ún ṣékélì owó fàdákà fún baba ọmọbìnrin náà, nítorí ọkùnrin yìí ti fi orúkọ búburú fún wúńdíá Israẹli. Yóò máa ṣe ìyàwó rẹ̀; gbọdọ̀ kọ̀ ́ sílẹ̀ gbogbo ayé e rẹ̀.

20 Ṣùgbọ́n ̀sùn náà jẹ́ òtítọ́ a ̀ìbálé obìnrin náà, 21 22.21: 1Kọ 5.13.wọn yóò ẹnu-ọ̀ilé baba rẹ̀ níbẹ̀ ni àwọn ọkùnrin ìlú rẹ̀ yóò ti sọ ́ òkúta pa. Ó ti ṣe ohun ìtìjú Israẹli nípa ṣíṣe àgbèrè nígbà ó nílé baba rẹ̀. láti pa ohun búburú kúrò láàrín yín.

22 o ọkùnrin kan ó ìyàwó ọkùnrin mìíràn lòpọ̀, àwọn méjèèjì láti . láti pa ohun búburú kúrò láàrín Israẹli.

23 ó ṣẹlẹ̀ ọkùnrin kan pàdé wúńdíá a ti fi fún ni láti fẹ́ láàrín ìlú ó lòpọ̀ pẹ̀u rẹ̀, 24 22.24: 1Kọ 5.13.ìwọ yóò àwọn méjèèjì lọ ẹnu ibodè ìlú náà o sọ wọ́n òkúta pa nítorí ọmọbìnrin náà ìlú kígbe fún ìrànlọ́wọ́, àti ọkùnrin náà nítorí ó ba ìyàwó ọkùnrin mìíràn jẹ́. O láti wẹ búburú kúrò láàrín rẹ.

25 Ṣùgbọ́n ó ṣe ìgbẹ́ ó ti ṣẹlẹ̀ ọkùnrin kan ti pàdé ọmọbìnrin a ti fẹ́ ṣọ́o fi tagbára tagbára a ṣe, ọkùnrin náà nìkan ó ṣe èyí ni yóò . 26 ṣe fi ohunkóhun ṣe ọmọbìnrin náà; ṣẹ ̀ṣẹ̀ ó tọ́ ikú. Ẹjọ́ yìí i ti ẹnìkan a gbámú ó pa aládùúgbò rẹ̀. 27 Nítorí ọkùnrin náà ọmọbìnrin náà ìta ibodè, ó tilẹ̀ jẹ́ ọmọbìnrin àfẹ́sọ́kígbe, ẹnìkankan níbẹ̀ láti gbà á kalẹ̀.

28 22.28,29: El 22.16,17. ó ṣẹlẹ̀ ọkùnrin pàdé wúńdíá ì ì àfẹ́sọ́ó fi tipátipá a ṣe a gbá wọn . 29 Ó láti san àádọ́ta fàdákà fún baba obìnrin náà, nítorí ó ti á jẹ́. kọ̀ ́ sílẹ̀ níwọ̀n ìgbà ó láààyè.

30 22.30: Le 18.8; 20.11; De 27.20. Ọkùnrin gbọdọ̀ fẹ́ ìyàwó baba rẹ̀; gbọdọ̀ sọ ìtẹ́ baba rẹ̀ di àìlọ́wọ̀.

Veja também