Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronomi 4

9 4.9-14: El 19.1–20.21. Kìkì i kíyèsára, ṣọ́ra a yín gidigidi ba à gbàgbé àwọn ohun ojú yín ti , wọn ṣe kúrò lóókan àyà yín níwọ̀n ìgbà láààyè. máa fi wọ́n kọ́ àwọn ọmọ yín àti àwọn ọmọ wọn ń bọ̀ lẹ́yìn wọn. 10 rántí ọjọ́ dúró níwájú Olúwa Ọlọ́run yín Horebu, nígbà ó fún mi , "àwọn ènìyàn wọ̀nyí jọ síwájú mi láti gbọ́ ̀rọ̀ mi, wọ́n kọ́ láti máa bu ọlá náà fún mi gbogbo ìgbà wọ́n gbé lórí ilẹ̀ náà, wọ́n le è fi wọ́n kọ́ àwọn ọmọ wọn."

Veja também