Publicidade

Deuteronômio 8

ṣe gbàgbé Olúwa

1 kíyèsi i láti máa tẹ̀gbogbo àṣẹ mo fún un yín lónìí, à le , pọ̀ i wọ ilẹ̀ náà, le gba ilẹ̀ náà, Olúwa búra ṣèlérí fún àwọn baba ńlá a yín. 2 rántí Olúwa Ọlọ́run yín ti tọ́ yín ṣọ́gbogbo ̀aginjù fún ogójì ọdún wọ̀nyí láti tẹ orí yín ba àti láti dán an yín ó ba à le mọ ọkàn yín ti , bóyá ó pa òfin rẹ̀ mọ́ tàbí bẹ́̀ kọ́. 3 8.3: Mt 4.4; Lk 4.4.Ó rẹ̀ yín sílẹ̀ nípa fífi ebi pa yín, Ó fi manna bọ́ yín, èyí mọ̀, àwọn baba yín mọ̀, ó ba à kọ́ yín , ènìyàn ti ipa oúnjẹ nìkan láààyè, ṣe ohun gbogbo ó jáde láti ẹnu Olúwa . 4 Aṣọ yín gbó mọ́ ọn yín lọ́rùn bẹ́̀ ẹsẹ̀ yín , ogójì ọdún náà. 5 mọ̀ ọkàn an yín , baba ti ń kọ́ ọmọ rẹ̀, bẹ́̀ ni Olúwa Ọlọ́run yín ń kọ́ yín.

6 Nítorí èyí, gbọdọ̀ pa òfin Olúwa Ọlọ́run yín mọ́, nípa rínrìn ̀rẹ̀, àti bíbẹ̀rẹ̀. 7 Nítorí Olúwa Ọlọ́run yín ń un yín bọ̀ ilẹ̀ rere ilẹ̀ ó kún fún odò àti ibú omi, pẹ̀àwọn ìsun ń sàn jáde láti orí òkè àti pẹ̀tẹ́lẹ̀. 8 Ilẹ̀ ó kún fún jéró àti ọkà barle, ó kún fún àjàrà àti igi ̀pọ̀tọ́, igi pomegiranate, òróró olifi àti oyin. 9 Ilẹ̀ oúnjẹ ti wọ́n, ohun ̀yin yóò ṣe aláìní, ilẹ̀ irin ti pọ̀ òkúta, ̀yin wa idẹ jáde láti inú òkè rẹ̀ .

10 Nígbà ti jẹ tán yin Olúwa Ọlọ́run yín fún pípèsè ilẹ̀ rere fún un yín. 11 8.11-16: Ho 13.5,6.ṣọ́ra gbàgbé Olúwa Ọlọ́run yín, nípa kíkùnà láti pa àṣẹ rẹ̀, àwọn òfin rẹ̀, àti àwọn ìlànà rẹ̀ mo ń fún un yín lónìí mọ́. 12 ó ba à jẹ́ , nígbà jẹun tán, kọ́ ilé ó dára tán, ń gbé inú rẹ̀, 13 nígbà àwọn agbo màlúù yín àti ewúrẹ́ yín pọ̀ i tán, fàdákà àti wúrà yín ń peléke i, ohun gbogbo ń pọ̀ i, 14 nígbà náà ni ọkàn yín yóò gbéga, ̀yin yóò gbàgbé Olúwa Ọlọ́run yín, ó un yín jáde láti Ejibiti , nínú oko ẹrú. 15 Òun ni ó un yín la aginjù ẹlẹ́ńlá , ilẹ̀ omi ó kún fún òǹgbẹ, pẹ̀àwọn ejò olóró ńlá ńlá àti àkéekèe. Ó omi jáde fún un yín láti inú àpáta. 16 Ó fún yín manna láti jẹ nínú aginjù, ohun àwọn baba yín mọ̀ , Òun à le tẹ orí yín ba ó dán an yín , ó à dára fún un yín. 17 nínú ara yín , "Agbára mi àti iṣẹ́ ọwọ́ mi ni ó ̀rọ̀ wọ̀nyí fún mi." 18 Ṣùgbọ́n rántí Olúwa Ọlọ́run yín ó fún un yín agbára àti àwọn ọrọ̀ wọ̀nyí, ó fi májẹ̀rẹ̀ ṣẹ ó ti búra fún àwọn baba ńlá a yín ó ti lónìí.

19 gbàgbé Olúwa Ọlọ́run yín, tẹ̀àwọn òrìṣà mìíràn, sìn wọ́n, foríbalẹ̀ fún wọn, Mo kìlọ̀ fún un yín rírun ni ̀yin yóò run. 20 àwọn orílẹ̀-èdè Olúwa parun níwájú u yín, bákan náà ni ó parun, torí gbọ́rọ̀ Olúwa Ọlọ́run yín lẹ́nu.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-