Publicidade

Êxodo 1

A ni àwọn ọmọ Israẹli lára

1 Ìwọ̀nyí ni àwọn orúkọ ọmọ Israẹli wọ́n Jakọbu lọ Ejibiti, ẹnìkọ̀̀kan pẹ̀ìdílé rẹ̀:

2 Reubeni, Simeoni, Lefi àti Juda;

3 Isakari, Sebuluni àti Benjamini;

4 Dani àti Naftali;

Gadi àti Aṣeri.

5 Àwọn ìran Jakọbu jẹ́ àádọ́rin àpapọ̀; Josẹfu ti Ejibiti.

6 Wàyí o, Josẹfu àti gbogbo àwọn arákùnrin rẹ̀ àti gbogbo ìran náà , 7 ṣùgbọ́n àwọn ará Israẹli ń i, wọ́n ń pọ̀ i gidigidi, wọ́n òǹkà ó fi jẹ́ wọ́n kún ilẹ̀ náà.

8 Nígbà náà ni ọba tuntun mìíràn mọ Josẹfu jẹ ilẹ̀ Ejibiti. 9 Ó sọ fún àwọn ènìyàn rẹ̀, "ó, àwọn ará Israẹli ti pọ̀ iye àti agbára fún wa. 10 , jẹ́ a lo ọgbọ́n àlùmọ̀kọ́rọ́láti wọn lẹ́kun, ṣe bẹ́̀ wọn yóò túbọ̀ máa pọ̀ i. ogun bẹ́ sílẹ̀, wọn yóò darapọ̀ mọ́ àwọn ̀wa, wọn yóò da ojú ìjà kọ , wọn yóò àsálà kúrò ilẹ̀ yìí."

11 Nítorí náà, wọ́n yan àwọn ̀akóniṣiṣẹ́ wọn lórí láti máa ni wọ́n lára pẹ̀iṣẹ́ àṣekára. Wọ́n kọ́ Pitomi àti Ramesesi gẹ́gẹ́ ìlú ìṣúra pamọ́ fún Farao. 12 Ṣùgbọ́n a ti ń ni wọ́n lára , bẹ́̀ ni wọ́n ń pọ̀ i, wọ́n ń tànkálẹ̀. Nítorí náà, àwọn ará Ejibiti bẹ̀nítorí àwọn ará Israẹli. 13 Àwọn ará Ejibiti àwọn ọmọ Israẹli sìn àsìnpa. 14 Wọ́n wọn gbé ìgbé ayé kíkorò nípa iṣẹ́ bíríkì àti àwọn onírúurú iṣẹ́ oko; àwọn ará Ejibiti ń wọ́n ìlòkulò.

15 Ọba Ejibiti sọ fún àwọn agbẹ̀Heberu ti orúkọ wọn ń jẹ́ Ṣifura àti Pua , 16 "Nígbà ti ̀yin ń gbẹ̀àwọn obìnrin Heberu, kíyèsi wọn lórí ìkúnlẹ̀ ìrọbí wọn, ó jẹ́ ọkùnrin ni ọmọ náà, pa á; ṣùgbọ́n ó jẹ́ obìnrin, jẹ́ ó láààyè." 17 Ṣùgbọ́n àwọn agbẹ̀bẹ̀Ọlọ́run, wọn ṣe gẹ́gẹ́ ọba Ejibiti ti fún wọn; wọ́n jẹ́ àwọn ọmọkùnrin láààyè. 18 Ọba Ejibiti pe àwọn agbẹ̀ó béèrè lọ́wọ́ wọn , "Èéṣe ̀yin fi ṣe èyí? Èéṣe ̀yin fi àwọn ọmọkùnrin si?"

19 Àwọn agbẹ̀náà Farao lóhùn , "Àwọn obìnrin Heberu àwọn obìnrin Ejibiti, wọ́n agbára, wọ́n ti máa ń ọmọ àwọn agbẹ̀̀dọ̀ wọn."

20 Nítorí náà Ọlọ́run ṣàánú fún àwọn agbẹ̀náà, àwọn ọmọ Israẹli ń le i, wọ́n ń pọ̀ i jọjọ. 21 Nítorí àwọn agbẹ̀bẹ̀Ọlọ́run, Ọlọ́run fún wọn ni ìdílé tiwọn.

22 Nígbà náà ni Farao pàṣẹ yìí fún gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀ , "Gbogbo ọmọkùnrin a ni gbé sínú odò Naili, ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ọmọbìnrin ni jẹ́ wọn ó láààyè."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-