Publicidade

Êxodo 12

Àjọ ìrékọjá

1 Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni ni ilẹ̀ Ejibiti , 2 "Oṣù yìí ni yóò jẹ́ oṣù àkọ́kọ́ fún yín, oṣù àkọ́kọ́ nínú ọdún yín. 3 Sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn Israẹli ni ọjọ́ kẹwàá oṣù yìí, ọkùnrin kọ̀̀kan yóò ̀dọ́-àgùntàn kọ̀̀kan fún ìdílé rẹ̀, ̀kan fún agbo ilé kọ̀̀kan. 4 ìdílé kan kéré fún odidi ̀dọ́-àgùntàn kan, wọn ó ṣe àjọpín ̀kan pẹ̀aládùúgbò wọn ti ó sun mọ́ wọn wọ́n lo iye ènìyàn tiwọn jẹ láti ṣe òdínwọ̀n irú ̀dọ́-àgùntàn tiwọn yóò ìbámu pẹ̀ìwọ̀n ti ẹni kọ̀̀kan jẹ. 5 ̀dọ́-àgùntàn ìwọ yóò gbọdọ̀ jẹ́ akọ ọlọ́dún kan lábùkù, ìwọ lára àgbò tàbí ewúrẹ́. 6 Ṣe ìtọ́wọn títí di ọjọ́ kẹrìnlá oṣù yìí nígbà gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli yóò pa ẹran náà àfẹ̀mọ́júmọ́. 7 Wọn yóò lára ̀jẹ̀ ẹran náà, wọn yóò fi kan ̀gbẹ́ méjèèjì àti òkè ẹnu-ọ̀àbáwọlé níbi wọ́n ti jẹ ẹran ̀dọ́-àgùntàn náà. 8 òru ọjọ́ kan náà, wọn yóò jẹ ẹran a ti fi iná sun, pẹ̀ewé ewúro àti àkàrà aláìwú. 9 ṣe jẹ ẹran náà ni tútù tàbí bíbọ̀ nínú omi, ṣùgbọ́n fi iná sun orí, ẹsẹ̀ àti àwọn nǹkan inú ẹran náà. 10 ṣe fi èyíkéyìí sílẹ̀ di òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ó ṣẹ́di òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, o níná. 11 Báyìí ni ̀yìn yóò ṣe jẹ́ ̀yin ti àmùrè ̀gbẹ́ yín, sáńdà yín ẹsẹ̀ yín àti ̀yín ni ọwọ́ yín. yára jẹ ́, oúnjẹ àjọ ìrékọjá Olúwa ni.

12 "òru ọjọ́ yìí kan náà ni Èmi yóò la gbogbo ilẹ̀ Ejibiti kọjá, èmi yóò pa gbogbo àkọ́àti ènìyàn, àti ẹranko, èmi yóò ìdájọ́ orí àwọn òrìṣà ilẹ̀ Ejibiti. Èmi ni Olúwa." 13 ̀jẹ̀ ni yóò jẹ́ àmì fún un yín àwọn ilé ̀yin , nígbà èmi ̀jẹ̀ náà, Èmi yóò e yín kọjá. Ààrùn kan yóò kàn yín nígbà èmi kọlu Ejibiti láti pa wọ́n run.

14 "Ọjọ́ òní ni yóò máa ṣe ọjọ́ ìrántí fún yín, ́yin yóò máa láàrín àwọn ìran ó ń bọ̀ lẹ́yìn ni ̀yin yóò ti máa ṣe àjọ fún Olúwa; ìran-ìran yín ìlànà yóò títí ayé. 15 Fún ọjọ́ méje ni ̀yin yóò fi jẹ àkàrà ìwúkàrà. ọjọ́ kìn-ín-ní, ó gbé ìwúkàrà kúrò ni ilé yín, nítorí ẹnikẹ́ni ó jẹ ohunkóhun ó ni ìwúkàrà nínú láti ọjọ́ kìn-ín-ní di ọjọ́ keje ni a yọ kúrò ni Israẹli. 16 ọjọ́ kìn-ín-ní àpéjọ mímọ́ ó ; àti ọjọ́ keje àpéjọ mímọ́ mìíràn yóò fún yín. ṣe ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ kan àwọn ọjọ́ wọ̀nyí, ṣe oúnjẹ olúkúlùkù yóò jẹ; kìkì èyí ni gbogbo ohun ̀yin ṣe.

17 "ó kíyèsí àjọ àìwúkàrà, nítorí ọjọ́ náà gan an ni mo ogun yín jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti. Nítorí náà ni máa kíyèsi ọjọ́ náà ìran-ìran yín ìlànà yóò títí ayé. 18 Àkàrà ti ni ìwúkàrà ni ̀yin yóò jẹ láti ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kẹrìnlá títí di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kọ̀kànlélógún oṣù àkọ́kọ́. 19 Fún ọjọ́ méje ni gbọdọ̀ ni ìwúkàrà nínú ilé yín, ẹnikẹ́ni ó jẹ ohun ó ni ìwúkàrà nínú ni a ó yọ kúrò ni àárín àwùjọ Israẹli, ìbá à ṣe àlejò tàbí ẹni a ilẹ̀ náà. 20 gbọdọ̀ jẹ ohunkóhun a fi ìwúkàrà ṣe. ibikíbi ̀yin ń gbé, ̀yin ó jẹ àkàrà ìwúkàrà."

21 ìgbà náà ni Mose gbogbo àwọn àgbàgbà Israẹli jọ, ó sọ fún wọn , "jáde lọ, yan ̀dọ́-àgùntàn fún àwọn ìdílé yín, pa ẹran àjọ ìrékọjá Olúwa. 22 ̀yin yóò ìdí-ewé hísópù, í bọ inú ̀jẹ̀ ó nínú ọpọ́n fi kun òkè à wọ ẹnu-ọ̀ilé yín àti ̀gbẹ́ méjèèjì ìlẹ̀kùn yín. Ẹnikẹ́ni nínú yín gbọdọ̀ jáde òde títí di òwúrọ̀. 23 ìgbà Olúwa ń lọ káàkiri ilẹ̀ Ejibiti láti kọlù wọn, yóò ̀jẹ̀ ni òkè ẹnu-ọ̀àti ni ̀gbẹ́ ẹnu-ọ̀ilé yín, yóò ẹnu-ọ̀ilé náà kọjá, yóò gba apanirun láààyè láti wọ inú ilé e yín láti kọlù yín.

24 "pa ìlànà yìí mọ́ gẹ́gẹ́ ohun ó máa ṣe títí ayérayé láàrín yín àti àwọn ìran yín. 25 Nígbà ̀yin de ilẹ̀ Olúwa yóò fi fún un yín òun ti ṣe ìlérí, máa kíyèsi àjọ yìí. 26 ìgbà àwọn ọmọ yín béèrè lọ́wọ́ yín, ni ohun àjọ yìí túmọ̀ fún un yín?27 sọ fún wọn ni ìgbà náà, Ẹbọ ìrékọjá Olúwa ni, ẹni ó rékọjá ilé àwọn ọmọ Israẹli ni ìgbà ó kọlu àwọn ara Ejibiti. ó si da wa nígbà ti ó pa àwọn ara Ejibiti.’ " Àwọn ènìyàn tẹríba láti sìn. 28 Àwọn ọmọ Israẹli ṣe gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose àti Aaroni.

29 ̀gànjọ́ òru Olúwa kọlu gbogbo àwọn àkọ́ilẹ̀ Ejibiti, láti orí àkọ́. Farao ó orí ìtẹ́ títí orí àkọ́ẹlẹ́wọ̀n ó nínú túbú àti àkọ́ẹran ̀sìn pẹ̀. 30 Farao àti àwọn ìjòyè rẹ̀ àti gbogbo àwọn ara Ejibiti dìde ̀gànjọ́ òru, igbe ẹkún ńlá gba gbogbo ilẹ̀ Ejibiti, nítorí ilé kan ó yọ sílẹ̀ ènìyàn kan ti .

Ìjáde lọ

31 Farao ránṣẹ́ pe Mose àti Aaroni òru, ó , "kúrò lọ́dọ̀ mi ̀yin àti àwọn ènìyàn Israẹli! lọ láti sin Olúwa gẹ́gẹ́ ti béèrè. 32 agbo àgùntàn yín àti agbo màlúù yín gẹ́gẹ́ ̀yin ti sọ, máa lọ, súre fún mi."

33 Àwọn ara Ejibiti ń rọ àwọn ènìyàn náà láti yára máa lọ kúrò ilẹ̀ wọn. Wọ́n , "bẹ́̀ kọ́ gbogbo wa ni yóò !" 34 Àwọn ènìyàn náà ìyẹ̀fun púpọ̀ wọn fi ìwúkàrà i, wọ́n gbe le èjìká wọn nínú ọpọ́n wọ́n ti fi aṣọ . 35 Àwọn ọmọ Israẹli ṣe gẹ́gẹ́ Mose ti sọ fún wọn. Wọ́n béèrè lọ́wọ́ ará Ejibiti fún ohun èlò fàdákà àti wúrà àti fún aṣọ pẹ̀. 36 Olúwa ti àwọn ènìyàn yìí ojúrere àwọn ará Ejibiti wọ́n fún wọn ohun wọ́n béèrè fún, wọ́n ko ẹrù àwọn ará Ejibiti.

37 Àwọn ọmọ Israẹli rìn láti Ramesesi lọ Sukkoti. Àwọn ọkùnrin ń fi ẹsẹ̀ rìn ọgbọ̀n ̀kẹ́ (600,000) ni iye láìka àwọn obìnrin àti àwọn ọmọdé. 38 ̀pọ̀ àwọn ènìyàn mìíràn ni ó wọ́n lọ àti ̀pọ̀lọpọ̀ ẹran ̀sìn, agbo àgùntàn àti agbo màlúù. 39 Pẹ̀ìyẹ̀fun ìwúkàrà nínú wọ́n gbé jáde láti Ejibiti ni wọ́n fi ṣe àkàrà aláìwú. Ìyẹ̀fun náà ni ìwúkàrà nínú nítorí a wọn jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wọn si ààyè láti tọ́oúnjẹ fún ara wọn.

40 Iye ọdún ti àwọn ará Israẹli gbé ilẹ̀ Ejibiti jẹ́ irinwó ọdún ó ọgbọ̀n (430). 41 Ó òpin irinwó ọdún ó le ọgbọ̀n (430), ọjọ́ náà gan an, ni ó ṣe gbogbo ogun Olúwa jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti. 42 Nítorí , Olúwa ṣe àìsùn ni òru ọjọ́ náà láti wọn jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti, òru yìí ni gbogbo Israẹli láti máa ṣe àìsùn láti fi bu ọlá fún Olúwa títí di àwọn ìran ń bọ̀.

Òfin Àjọ ìrékọjá

43 Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni , "Ìwọ̀n yìí ni àwọn òfin fún àjọ ìrékọjá:

"Àjèjì gbọdọ̀ jẹ nínú rẹ̀. 44 Ẹrú ̀yin jẹ́ nínú rẹ̀ lẹ́yìn ̀yin ti kọ ́ ilà, 45 ṣùgbọ́n àtìpó àti alágbàṣe ni jẹ nínú rẹ̀.

46 "Nínú ilé ni ti gbọdọ̀ jẹ ́; gbọdọ̀ èyíkéyìí nínú ẹran náà jáde kúrò nínú ilé. ṣe ṣẹ́ ̀kankan nínú egungun rẹ̀. 47 Gbogbo àjọ Israẹli ni ó gbọdọ̀ ṣe àjọyọ̀ rẹ̀.

48 "Àjèjì ti ó ń gbé àárín yín ti ó fẹ́ kópa nínú àjọ ìrékọjá Olúwa, ni o gbọdọ̀ kọ gbogbo àwọn ọmọkùnrin ilé rẹ̀ ilà; ìgbà náà ni ó ipa gẹ́gẹ́ àwọn ọmọ a ilẹ̀ náà. Gbogbo àwọn ọmọkùnrin a kọ ilà, wọ́n ni jẹ nínú rẹ̀. 49 Òfin yìí kan náà ni ó àwọn ọmọ a ni ilẹ̀ náà àti àwọn àlejò ń gbé àárín yín."

50 Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ṣe gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose àti Aaroni. 51 Àti ọjọ́ náà gan an ni Olúwa àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti gẹ́gẹ́ ìpín ìpín wọn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-