Publicidade

Êxodo 19

orí òkè Sinai

1 oṣù kẹta àwọn Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti, ni ọjọ́ náà gan an ni wọ́n aginjù Sinai. 2 Lẹ́yìn ìgbà wọ́n gbéra kúrò Refidimu, wọ́n wọ ijù Sinai, wọ́n tẹ̀síbẹ̀, níbẹ̀ ni Israẹli iwájú òkè ńlá.

3 Mose gòkè tọ Ọlọ́run lọ. Olúwa é láti orí òkè náà , "Èyí ni ìwọ yóò sọ fún ilé Jakọbu àti ohun ìwọ yóò sọ fún àwọn ọmọ Israẹli: 4 ̀yin ti ohun mo ti ṣe àwọn ará Ejibiti, àti mo ti gbé e yín apá ìyẹ́ idì. 5 Nísinsin yìí, ̀yin ṣe ìgbọ́ràn mi ojú àmì, pa májẹ̀mi mọ́, nígbà náà ni ̀yin ó jẹ́ ìṣúra fún mi ju gbogbo orílẹ̀-èdè yòókù lọ. ó tilẹ̀ jẹ́ gbogbo ayé ni tèmi. 6 ̀yin yóò máa jẹ́ ilẹ̀ ọba àwọn àlùfáà fún mi, orílẹ̀-èdè mímọ́.’ Ìwọ̀nyí ni ̀rọ̀ ti ìwọ yóò sọ fún àwọn ọmọ Israẹli."

7 Mose tọ àwọn ènìyàn , ó pe àwọn àgbàgbà láàrín àwọn ènìyàn jọ. Ó gbé gbogbo ̀rọ̀ ti Olúwa pàṣẹ fún un láti sọ iwájú wọn. 8 Gbogbo àwọn ènìyàn náà pa ohùn wọn pọ̀ wọ́n dáhùn , "Àwa yóò ṣe ohun gbogbo ti Olúwa ." Mose ìdáhùn wọn padà tọ Olúwa lọ.

9 Olúwa sọ fún Mose , "Èmi yóò tọ̀ ́ nínú ìkùùkuu ṣíṣú dudu, àwọn ènìyàn gbọ́ ohùn mi nígbà ti mo ń sọ̀rọ̀, wọn ó máa gbà ́ gbọ́." Nígbà náà ni Mose sọ ohun àwọn ènìyàn fún Olúwa.

10 Olúwa fún Mose , "Tọ àwọn ènìyàn lọ o wọ́n mímọ́ ni òní àti ni ̀la. Jẹ́ wọn ó fọ aṣọ wọn. 11 wọn ó múra di ọjọ́ kẹta, nítorí ni ọjọ́ náà ni Olúwa yóò sọ̀kalẹ̀ orí òkè Sinai ni ojú gbogbo àwọn ènìyàn. 12 ìwọ ó ṣe ààlà fún àwọn ènìyàn, ìwọ ó fún wọn , kíyèsí ara yín, ṣe gun orí òkè lọ, tilẹ̀ fi ọwọ́ ba etí rẹ̀; ẹnikẹ́ni ó fi ọwọ́ kan òkè náà, ó dájú, pípa ni a ó pa á. 13 A ó sọ ́ òkúta tàbí a ta á ọfà, ọwọ́kọ́wọ́ gbọdọ̀ kàn án. Ìbá à ṣe ènìyàn tàbí ẹranko, òun yóò láààyè.Nígbà ti ìpè dún nìkan ni wọn ó gun òkè ."

14 Mose sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè náà ̀dọ̀ àwọn ènìyàn, ó wọ́n mímọ́, wọ́n fọ aṣọ wọn. 15 Ó sọ fún àwọn ènìyàn , "múra sílẹ̀ di ọjọ́ kẹta; ṣe aya yín lòpọ̀."

16 òwúrọ̀ ọjọ́ kẹta, àrá àti mọ̀nàmọ́pẹ̀ìkùùkuu ó ṣú dudu orí òkè, ìpè ńlá dún kíkankíkan bẹ́̀ gbogbo àwọn ó ni ibùdó wárìrì. 17 Mose àwọn ènìyàn ó jáde láti ibùdó pàdé Ọlọ́run, wọ́n dúró nítòsí òkè. 18 Èéfín bo òkè Sinai nítorí Olúwa sọ̀kalẹ̀ orí rẹ̀ nínú iná. Èéfín náà ń ru sókè èéfín iná ìléru, gbogbo òkè náà tìtì. 19 Ohùn ìpè ń rinlẹ̀ dòdò. Mose sọ̀rọ̀, Ọlọ́run fi àrá a lóhùn.

20 Olúwa sọ̀kalẹ̀ orí òkè Sinai, o pe Mose orí òkè náà. Mose gun orí òkè. 21 Olúwa sọ fún Mose , "Sọ̀kalẹ̀, ó kìlọ̀ fún àwọn ènìyàn, wọn ṣe fi tipátipá ̀láti wo Olúwa, wọn ṣe bẹ́̀, ̀pọ̀ wọn yóò ṣègbé. 22 Kódà àwọn àlùfáà ó ń síwájú Olúwa gbọdọ̀ ya ara wọn mímọ́ bẹ́̀ kọ́. Olúwa yóò kọlù wọ́n."

23 Mose fún Olúwa , "Àwọn ènìyàn yóò orí òkè Sinai, nítorí ìwọ fúnra rẹ̀ ti kìlọ̀ fún wa , Ṣe ààlà òkè , o á mímọ́.’ "

24 Olúwa fún Mose , "Sọ̀kalẹ̀ lọ, Aaroni gòkè pẹ̀rẹ. Ṣùgbọ́n àwọn àlùfáà àti àwọn ènìyàn ṣe fi tipátipá gòkè tọ Olúwa. bẹ́̀ kọ́ yóò kọlù wọ́n."

25 Mose sọ̀kalẹ̀ tọ àwọn ènìyàn lọ. Ó sọ ohun Olúwa fún wọn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-