Publicidade

Êxodo 3

Mose àti igbó ń

1 ọjọ́ kan nígbà Mose ń ṣọ́ agbo ẹran Jetro baba ìyàwó rẹ̀, àlùfáà Midiani. Ó da agbo ẹran náà lọ ̀jíjìn nínú aginjù. Ó Horebu, òkè Ọlọ́run. 2 Níbẹ̀ ni angẹli Olúwa ti yọ i nínú ̀wọ́-iná ń láàrín igbó. Mose i iná ń nínú igbó ṣùgbọ́n igbó run. 3 Nígbà náà ni Mose sọ , "Èmi yóò lọ wo ohun ìyanu yìí, ìdí iná fi igbó run."

4 Nígbà Olúwa i pe Mose ti lọ láti lọ ó, Ọlọ́run é láti àárín igbó náà, "Mose! Mose!"

Mose dáhùn ó , "Èmi nìyìí."

5 Olúwa fún Mose , "ṣe súnmọ́ ìhín yìí, bọ́ sálúbàtà rẹ kúrò ẹsẹ̀ rẹ, nítorí ibi ìwọ dúró i ilẹ̀ mímọ́ ni." 6 Nígbà náà ó , "Èmi ni Ọlọ́run baba rẹ, Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki àti Ọlọ́run Jakọbu." Nítorí ìdí èyí, Mose pa ojú rẹ̀ mọ́, nítorí ó bẹ̀láti bojú wo Ọlọ́run.

7 Olúwa si , "Èmí ti ìpọ́njú àwọn ènìyàn mi ilẹ̀ Ejibiti, mo ti gbọ́ ohùn igbe wọn nítorí àwọn akóniṣiṣẹ́ wọn. Ìyà ń jẹ wọ́n kan mi lára. 8 Èmi ti sọ̀kalẹ̀ láti gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn ará Ejibiti, àti láti wọn gòkè kúrò ilẹ̀ náà lọ ilẹ̀ ó dára ó ààyè, àní ilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti oyin; ibùgbé àwọn ará Kenaani, ará Hiti, Amori, Peresi, Hifi àti Jebusi. 9 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ó, igbe àwọn ará Israẹli ti ̀dọ̀ mi, Èmi ti àwọn ará Ejibiti ti ṣe ń gbà ń jẹ wọ́n ìyà. 10 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, lọ, èmi yóò rán Farao láti àwọn ènìyàn Israẹli jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti."

11 Ṣùgbọ́n Mose fún Ọlọ́run , "Ta ni èmi, èmi yóò tọ Farao lọ, ti èmi yóò àwọn ará Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti?"

12 Nígbà náà ni Ọlọ́run fún Mose , "Èmi yóò pẹ̀rẹ. Èyí ni yóò jẹ́ àmì fún , yóò fihàn , èmi ni ó rán lọ, nígbà ìwọ àwọn ènìyàn náà jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti, ̀yin yóò sin Ọlọ́run ni orí òkè yìí."

13 Mose fún Ọlọ́run , "mo tọ àwọn ará Israẹli lọ mo sọ fún wọn , Ọlọ́run àwọn baba yín ni ó rán mi i yín,wọ́n béèrè lọ́wọ́ mi , ni orúkọ rẹ̀?’ ni èmi yóò sọ fún wọn ìgbà náà?"

14 Ọlọ́run sọ fún Mose , "èmi ni ti ń jẹ́ èmi ni. Èyí ni ìwọ yóò sọ fún àwọn ará Israẹli: èmi ni ni ó rán mi i yín.’ "

15 Ọlọ́run fún Mose pẹ̀, "Báyìí ni ìwọ sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín; Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki àti Ọlọ́run Jakọbu; ni ó rán mi i yín.

"Èyí ni orúkọ mi títí ayérayé,

orúkọ ti ó fi máa rántí mi

láti ìran ìran.

16 "Lọ, àwọn àgbàgbà Israẹli jọ, o fún wọn , Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín, Ọlọ́run Abrahamu, ti Isaaki, àti ti Jakọbu; ni ó farahàn mi, ó , lóòótọ́ èmi ti ń bojú yín, èmi ti ohun wọ́n ṣe i yín ni ilẹ̀ Ejibiti. 17 Èmi ti ṣe ìlérí láti un yín jáde kúrò nínú ìpọ́njú yín ni ilẹ̀ Ejibiti ilẹ̀ Kenaani, ará Hiti, Amori, Peresi, Hifi àti Jebusi; ilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti oyin.

18 "Àwọn àgbàgbà Israẹli yóò fetísílẹ̀ ohùn rẹ. Nígbà náà ni ìwọ, àti àwọn àgbàgbà yóò jọ tọ ọba Ejibiti lọ, ó fún un , Olúwa, Ọlọ́run àwọn ará Heberu ti pàdé wa. Jẹ́ a lọ ni ìrìn ọjọ́ mẹ́ta inú aginjù láti lọ ẹbọ Olúwa Ọlọ́run.19 Ṣùgbọ́n èmi mọ̀ ọba Ejibiti jẹ́ lọ ṣe ọwọ́ ńlá Ọlọ́run ni ara rẹ̀. 20 Nítorí náà, èmi yóò na ọwọ́ láti lu àwọn ará Ejibiti pẹ̀gbogbo ohun ìyanu èmi yóò ṣe ni àárín wọn. Lẹ́yìn náà, òun yóò jẹ́ máa lọ.

21 "Èmi yóò jẹ́ ojúrere àwọn ará Ejibiti pàdé. yóò fi jẹ́ ti ̀yin ń lọ, lọ ọwọ́ òfo. 22 Gbogbo àwọn obìnrin ni ó láti béèrè lọ́wọ́ àwọn aládùúgbò wọn àti gbogbo àwọn obìnrin ti ń gbé nínú ilé rẹ fún ohun fàdákà àti wúrà àti fún aṣọ, èyí ti ̀yin yóò wọ̀ ọrùn àwọn ọmọ yín ọkùnrin àti obìnrin. Báyìí ni ̀yin yóò ẹrù àwọn ará Ejibiti."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-