Pular para o conteúdo
Publicidade

Êxodo 32

11 Ṣùgbọ́n Mose kígbe fún ojúrere Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, ó , "Olúwa, èéṣe ìbínú rẹ yóò ṣe gbóná àwọn ènìyàn rẹ, ìwọ jáde láti Ejibiti pẹ̀agbára ńlá àti ọwọ́ agbára? 12 Èéṣe àwọn ará Ejibiti yóò ṣe , Nítorí ibi ni ó ṣe mọ̀ ́n mọ̀ wọn jáde, láti pa wọ́n orí òkè àti láti gbá wọn kúrò lórí ayé? Yípadà kúrò nínú ìbínú rẹ ó múná, ọkàn padà, o ṣe ìparun sórí àwọn ènìyàn rẹ. 13 Rántí àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ Abrahamu, Isaaki àti Israẹli, ẹni ìwọ búra fún fúnra rẹ̀, o fún wọn , Èmi yóò irú-ọmọ rẹ pọ̀ ìràwọ̀ ojú ̀run, Èmi yóò fún irú-ọmọ rẹ gbogbo ilẹ̀ mo ti pinnu fún wọn, yóò jẹ́ ogún ìní wọn láéláé.’ " 14 Nígbà náà ni Olúwa dáwọ́ ìbínú rẹ̀ dúró, ìparun náà ó sọ sórí àwọn ènìyàn rẹ̀ mọ́.

Veja também