Pular para o conteúdo
Publicidade

Êxodo 4

Àwọn àmì fún Mose

1 Mose dáhùn ó , "Ṣùgbọ́n wọn gbà gbọ́ ń kọ́? Tàbí wọn fi etí sílẹ̀ láti gbọ́ ̀rọ̀ ẹnu mi, wọn , Olúwa farahàn ́’?"

2 ìgbà náà ni Olúwa sọ fún un , "ni ó ọwọ́ rẹ n ?"

Ó dáhùn , "̀ni."

3 Olúwa sọ , "Sọ ̀náà sílẹ̀."

Mose sọ ̀náà sílẹ̀, lọ́gán ni ̀náà di ejò, ó fún un. 4 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún un , "Na ọwọ́ rẹ, o un ni ìrù." Mose na ọwọ́ rẹ̀, ó mu ejò náà, ejò náà padà di ̀ó ni ọwọ́ rẹ̀. 5 Olúwa , "Èyí bẹ́̀ wọn à le è gbàgbọ́ , Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn, Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki, àti Ọlọ́run Jakọbu; farahàn ́."

6 ìgbà náà ni Olúwa , "Ti ọwọ́ rẹ bọ inú aṣọ igbá àyà rẹ̀." Mose ti ọwọ́ rẹ̀ bọ inú aṣọ igbá àyà rẹ̀, ìgbà ti ó yọ ́ jáde, ọwọ́ rẹ̀ ti dẹ́tẹ̀, ó ti funfun ̀gbọ̀n òwú.

7 Ó , "Nísinsin yìí, fi ọwọ́ náà padà abẹ́ aṣọ igbá àyà rẹ." Mose ṣe bẹ́̀, ọwọ́ rẹ̀ padà bọ́ sípò àwọn ̀ara rẹ̀ tókù.

8 ìgbà náà ni Olúwa , "wọn gbà ́ gbọ́ tàbí kọ ibi ara iṣẹ́ ìyanu àkọ́kọ́, wọ́n le è ti ipasẹ̀ iṣẹ́ ìyanu kejì gbàgbọ́. 9 Ṣùgbọ́n wọn gba àmì méjèèjì wọ̀nyí gbọ́, wọn fetí ̀rọ̀ rẹ, bu omi díẹ̀ láti inú odò Naili o si á orí ìyàngbẹ ilẹ̀, omi ìwọ láti inú odò yìí yóò di ̀jẹ̀."

10 Mose sọ fún Olúwa , "Èmi jẹ́ akólòlò, èmi í ṣe ẹni sọ̀rọ̀ gaara láti ìgbà àtijọ́ tàbí láti ìgbà ti o ti ń ìránṣẹ́ rẹ sọ̀rọ̀, mo jẹ́ ẹni ti ahọ́n rẹ̀ lọ́, ó ń lọ́ra àti sọ̀rọ̀."

11 Olúwa sọ fún un , "Ta ni ó fún ènìyàn ni ẹnu? Ta ni ó un ya odi tàbí adití? Ta ni ó un ríran, tàbí un fọ́? Ǹjẹ́ í ṣe èmi Olúwa? 12 Lọ nísinsin yìí, Èmi yóò ràn ́ lọ́wọ́ láti sọ̀rọ̀. Èmi yóò kọ́ ni ohun ti ìwọ yóò sọ."

13 Mose dáhùn ó , "Olúwa jọ̀wọ́ rán ẹlòmíràn láti lọ ṣe iṣẹ́ yìí."

14 Ìbínú Olúwa ru sókè Mose, ó sọ , "Aaroni ará Lefi arákùnrin rẹ ń kọ́? Mo mọ̀ ó sọ̀rọ̀ gaara, ó ti ̀rẹ̀ báyìí láti pàdé e rẹ. Inú rẹ̀ yóò dùn ti ó . 15 Ìwọ yóò sọ̀rọ̀ fún un, ìwọ yóò fi ̀rọ̀ i lẹ́nu, èmi yóò ràn yín lọ́wọ́ láti sọ̀rọ̀. Èmi yóò kọ́ yín ni ohun ti ó ṣe. 16 Òun yóò sọ̀rọ̀ àwọn ènìyàn, yóò dàbí i ẹnu un rẹ ni a gbà sọ ̀rọ̀ náà, ìwọ yóò dàbí Ọlọ́run iwájú rẹ̀. 17 Ṣùgbọ́n ̀yìí ni ọwọ́ rẹ ìwọ à fi ṣe àwọn iṣẹ́ àmì ìyanu pẹ̀rẹ̀."

Mose padà Ejibiti

18 Mose padà ̀dọ̀ Jetro baba ìyàwó rẹ̀, ó sọ fún un , "Jọ̀wọ́ jẹ́ n padà tọ àwọn ènìyàn mi lọ ni ilẹ̀ Ejibiti láti bóyá wọ́n ṣì láààyè síbẹ̀."

Jetro dáhùn, ó , "Máa lọ ni àlàáfíà."

19 4.19: Ap 7.34. Nísinsin yìí, Olúwa ti sọ fún Mose ni ilẹ̀ Midiani , "Máa padà lọ Ejibiti, nítorí àwọn ti ó fẹ́ pa ti ." 20 Mose ìyàwó rẹ̀ àti àwọn ọmọ rẹ̀, ó wọn orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ó bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò rẹ̀ padà Ejibiti. Ó ̀Ọlọ́run ọwọ́ rẹ̀.

21 Olúwa sọ fún Mose , "ìgbà ìwọ padà Ejibiti i ìwọ ṣe iṣẹ́ ìyanu ni iwájú Farao. Èmi ti fún lágbára láti ṣe é. Èmi yóò àyà rẹ̀ le, òun yóò jẹ́ àwọn ènìyàn náà ó lọ. 22 Lẹ́yìn náà, o sọ fún Farao , Èyí ni Olúwa sọ: Israẹli àkọ́ọmọ mi ọkùnrin, 23 4.23: Ek 12.29.mo sọ fún , "Jẹ́ ọmọ mi lọ, ki òun ó máa sìn ." Ṣùgbọ́n ìwọ kọ̀ láti jẹ́ ó lọ; nítorí náà, èmi yóò pa àkọ́ọmọ rẹ ọkùnrin.’ "

24 ̀ìrìnàjò rẹ, ni ibi wọ́n gbé sùn ilé èrò alẹ́, Olúwa pàdé Mose, ó fẹ́ láti pa á. 25 Ṣùgbọ́n Sippora ̀bẹ òkúta mímú, ó kọ ọmọ rẹ̀ ilà abẹ́, ó fi awọ rẹ̀ kan ẹsẹ̀ Mose. Sippora , "Ọkọ ẹlẹ́jẹ̀ ni ìwọ jẹ́ mi." 26 Nítorí náà Olúwa yọ̀ǹda rẹ láti ìgbà ó ti , "Ẹlẹ́jẹ̀ ni ìwọ í ṣe." Èyí túmọ̀ ìkọlà abẹ́.

27 Olúwa sọ fún Aaroni , "Lọ sínú aginjù láti lọ pàdé Mose." ìgbà náà ni ó lọ pàdé Mose orí òkè Ọlọ́run, ó fi ẹnu ó ẹnu. 28 ìgbà náà ni Mose sọ ohun gbogbo Ọlọ́run ti rán fún Aaroni àti nípa gbogbo iṣẹ́ ìyanu Olúwa ti pàṣẹ fún un láti ṣe iwájú Farao.

29 Mose àti Aaroni pe gbogbo àwọn àgbàgbà Israẹli jọ. 30 Aaroni sọ ohun gbogbo Olúwa sọ fún Mose fún wọn, ó ṣe iṣẹ́ àmì náà ojú àwọn ènìyàn náà. 31 Wọ́n gbàgbọ́. Nígbà wọ́n gbọ́ Olúwa ti bẹ àwọn ọmọ Israẹli àti Olúwa ti gbọ́ nípa ìpọ́njú wọn, wọ́n tẹríba, wọ́n sìn ín. Ó ṣe àwọn iṣẹ́ àmì náà níwájú àwọn ènìyàn náà.

Veja também