Publicidade

Êxodo 40

Gbígbé àgọ́

1 Olúwa fún Mose , 2 "ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kìn-ín-ní ni ó gbé àgọ́ náà, àgọ́ àjọ náà . 3 Gbé àpótí ̀inú rẹ̀, ó bo àpótí náà pẹ̀aṣọ títa. 4 Gbé tábìlì náà wọ ilé, o to àwọn ohun ó jẹ́ tirẹ̀ e lórí. Nígbà náà gbé ̀fìtílà wọlé, o to àwọn fìtílà rẹ̀. 5 Gbé pẹpẹ wúrà ti tùràrí iwájú àpótí ̀, o fi aṣọ títa ẹnu-ọ̀ara àgọ́ náà.

6 "Gbé pẹpẹ ẹbọ sísun iwájú ẹnu-ọ̀àgọ́ náà, àgọ́ àjọ; 7 gbé agbada àárín àgọ́ àjọ àti pẹpẹ, o fi omi inú rẹ̀. 8 Gbé àgbàlá yìí ka, ó fi aṣọ títa ẹnu-ọ̀àgbàlá náà.

9 "òróró ìtasórí, ó ta á sára àgọ́ náà àti ohun gbogbo ó nínú rẹ̀, pẹpẹ mímọ́ àti gbogbo ̀ṣọ́ rẹ̀, yóò jẹ́ mímọ́. 10 Ta òróró sára pẹpẹ ẹbọ sísun àti gbogbo ohun èlò rẹ̀, ya pẹpẹ náà mímọ́, yóò jẹ́ mímọ́ jùlọ. 11 Ta òróró sára agbada náà àti ẹsẹ̀ rẹ, o wọ́n mímọ́.

12 "Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ ẹnu-ọ̀àgọ́ àjọ, o wẹ̀ wọ́n pẹ̀omi. 13 Nígbà náà wọ Aaroni aṣọ mímọ́, ta òróró i orí, o á mímọ́, nítorí ó máa sìn mi àlùfáà. 14 àwọn ọmọ rẹ̀ o fi aṣọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ wọ̀ wọ́n. 15 Ta òróró wọn orí gẹ́gẹ́ o ti ta òróró baba wọn orí, nítorí wọn máa sìn mi àlùfáà. Ìtasórí wọn yóò jẹ́ iṣẹ́ àlùfáà ti yóò máa fún gbogbo ìrandíran ń bọ̀." 16 Mose ṣe ohun gbogbo gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún un.

17 Bẹ́̀ ni wọ́n gbé àgọ́ náà ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kìn-ín-ní ọdún kejì. 18 Nígbà Mose gbé àgọ́ náà ó fi ihò ìtẹ̀bọ̀ ààyè rẹ̀, ó to pákó rẹ̀, ó fi ̀rẹ̀ bọ̀ ́, ó gbé àwọn òpó rẹ̀ . 19 Ó na aṣọ àgọ́ náà sórí àgọ́, ó fi ìbòrí bo orí àgọ́ náà, Olúwa ṣe pàṣẹ fún Mose.

20 Ó mu ̀, ó fi sínú àpótí, ó so àwọn òpó mọ́ àpótí náà, ó fi àánú bo orí rẹ. 21 Ó gbé àpótí náà sínú àgọ́; ó sọ aṣọ títa, ó ta á bo àpótí ̀, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

22 Mose gbé tábìlì sínú àgọ́ àjọ ìhà àríwá àgọ́ náà lẹ́yìn aṣọ títa, 23 40.23: Ek 25.30; 39.36; Le 24.5-9.ó to àkàrà sórí rẹ̀ níwájú Olúwa, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

24 Ó gbé ̀fìtílà sínú àgọ́ àjọ òdìkejì tábìlì ìhà gúúsù àgọ́ náà. 25 Ó tan àwọn fìtílà náà níwájú Olúwa, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

26 Mose gbé pẹpẹ wúrà sínú àgọ́ àjọ níwájú aṣọ títa 27 ó tùràrí dídùn lórí rẹ̀, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

28 Ó ta aṣọ títa ẹnu-ọ̀àgọ́ náà. 29 Ó gbé pẹpẹ ẹbọ sísun ̀gbẹ́ ẹnu-ọ̀àgọ́ àjọ, ó ẹbọ sísun àti ẹbọ oúnjẹ, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

30 40.30-32: Ek 30.18-21. Ó gbé agbada àárín àgọ́ àjọ àti pẹpẹ, ó pọn omi sínú rẹ̀ fún wíwẹ̀, 31 Mose, Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ ó láti fi wẹ ọwọ́ àti ẹsẹ̀ wọn. 32 Wọ́n máa ń wẹ̀ nígbàkígbà wọ́n wọ àgọ́ àjọ tàbí wọ́n súnmọ́ pẹpẹ, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

33 Mose gbé àgbàlá ó àgọ́ náà àti pẹpẹ, ó ta aṣọ títa ti ẹnu-ọ̀àgbàlá náà. Bẹ́̀ ni Mose ṣe parí iṣẹ́ náà.

Ògo Olúwa

34 40.34: If 15.8. Nígbà náà ni àwọsánmọ̀ bo àgọ́ àjọ, ògo Olúwa bo àgọ́ náà. 35 Mose wọ inú àgọ́ àjọ, nítorí àwọsánmọ̀ orí àgọ́, ògo Olúwa ti kún inú àgọ́ náà.

36 gbogbo ìrìnàjò àwọn ọmọ Israẹli nígbàkígbà a ti fa ìkùùkuu àwọsánmọ̀ náà sókè kúrò lórí àgọ́, wọ́n máa ń jáde lọ; 37 ṣùgbọ́n àwọsánmọ̀ gòkè wọn jáde títí di ọjọ́ ó gòkè. 38 Nítorí náà àwọsánmọ̀ Olúwa lórí àgọ́ ̀sán, iná nínú àwọsánmọ̀ alẹ́, ojú gbogbo ilé Israẹli gbogbo ìrìnàjò wọn.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-