Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 7

1 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose , "ó, Èmi ti ṣe Ọlọ́run fún Farao, Aaroni arákùnrin rẹ ni yóò jẹ́ agbẹnusọ rẹ. 2 Ìwọ yóò sọ ohun gbogbo Èmi ti pàṣẹ fún , Aaroni arákùnrin rẹ yóò sísọ fún Farao ó jẹ́ àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ rẹ̀. 3 7.3: Ap 7.36.Ṣùgbọ́n èmi yóò Farao lọ́kàn le. Mo tilẹ̀ ṣe ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ àmì àti ìyanu ni Ejibiti, 4 síbẹ̀ òun yóò fi etí . Nígbà náà ni Èmi yóò gbé ọwọ́ mi Ejibiti, pẹ̀agbára ìdájọ́ ńlá mi ni èmi yóò àwọn ènìyàn mi Israẹli jáde ̀wọ̀̀wọ́. 5 Àwọn ará Ejibiti yóò mọ̀ Èmi ni Olúwa ìgbà mo na ọwọ́ mi jáde Ejibiti, mo àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò níbẹ̀."

6 Mose àti Aaroni ṣe gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún wọn. 7 Mose jẹ́ ọmọ ọgọ́rin ọdún Aaroni jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́tàlélọ́gọ́rin ni ìgbà wọ́n Farao sọ̀rọ̀.

̀Mose di ejò

8 Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni, 9 "ìgbà Farao sọ fún un yín , ṣe iṣẹ́ ìyanu kan,sọ fún Aaroni ìgbà náà , ̀rẹ ó sọ ́ sílẹ̀ níwájú Farao,yóò di ejò."

10 Nígbà náà ni Mose àti Aaroni tọ Farao lọ, wọ́n ṣe Olúwa ti pàṣẹ fún wọn, Aaroni ju ̀rẹ̀ sílẹ̀ iwájú Farao àti àwọn ìjòyè rẹ̀, ̀náà di ejò. 11 Farao pe àwọn amòye, àwọn oṣó àti àwọn onídán ilẹ̀ Ejibiti jọ, wọ́n fi idán wọn ṣe ohun Mose àti Aaroni ṣe. 12 Ẹnìkọ̀̀kan wọn sọ ̀rẹ̀ sílẹ̀, ̀náà di ejò. Ṣùgbọ́n ̀Aaroni gbé ̀tiwọn . 13 Síbẹ̀ ọkàn Farao yigbì, si fetí wọn gẹ́gẹ́ Olúwa ti sọ.

Omí di ̀jẹ̀

14 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose , "Ọkàn Farao ti di líle, ó kọ̀ láti jẹ́ àwọn ènìyàn náà ó lọ. 15 Tọ Farao lọ ni òwúrọ̀ kùtùkùtù ó ti ń lọ etí odò, dúró ni etí bèbè odò Naili láti pàdé rẹ, ̀rẹ ó di ejò ni ọwọ́ rẹ. 16 Sọ fún un , Olúwa Ọlọ́run àwọn Heberu rán mi láti sọ fún , Jẹ́ àwọn ènìyàn mi ó lọ, wọn ó sìn mi ni aginjù. Ṣùgbọ́n títí di àkókò yìí, ìwọ gba. 17 7.17: If 16.4.Èyí ni Olúwa , nípa èyí ni ìwọ yóò mọ̀ Èmi ni Olúwa. ó, èmi yóò fi ̀ti ó ọwọ́ mi, èmi yóò omi ó nínú odò Naili yóò di ̀jẹ̀. 18 Àwọn ẹja ó nínú odò Naili yóò , odò náà yóò máa rùn, àwọn ará Ejibiti ni mu omi rẹ̀.’ "

19 Olúwa sọ fún Mose, "Sọ fún Aaroni, ̀rẹ ó na ọwọ́ rẹ jáde lórí àwọn omi Ejibiti. Lórí àwọn odò kéékèèké àti odò ńlá, lórí àbàtà àti adágún omi, wọn yóò di ̀jẹ̀.’ ̀jẹ̀ yóò ni ibi gbogbo ni Ejibiti, àní nínú ọpọ́n àti nínú kete omi àti nínú ìkòkò a pọn omi nínú ilé."

20 Mose àti Aaroni ṣe gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún wọn. Ó gbé ̀rẹ̀ sókè ni iwájú Farao àti àwọn ìjòyè rẹ̀, ó lu omi odò Naili, omi odò náà yípadà ̀jẹ̀. 21 Ẹja inú odò Naili , odò náà ń rùn gidigidi ó fi jẹ́ àwọn ará Ejibiti le è mu omi inú rẹ̀. ̀jẹ̀ ni ibi gbogbo ni ilẹ̀ Ejibiti.

22 Ṣùgbọ́n àwọn apidán ilẹ̀ Ejibiti ṣe bákan náà pẹ̀agbára òkùnkùn wọn, ọkàn Farao yigbì síbẹ̀ fetí wọn gẹ́gẹ́ Olúwa ti sọ. 23 Dípò bẹ́̀, ó yíjú padà, ó lọ ààfin rẹ̀, jẹ́ àwọn nǹkan wọ̀nyí ni oókan àyà rẹ̀. 24 Nígbà náà ni gbogbo àwọn ará Ejibiti bẹ̀rẹ̀ í gbẹ́ etí odò Naili láti omi wọn yóò mu, nítorí wọn le è mu omi ó nínú odò náà.

Àwọn ̀pọ̀lọ́ bo orí ilẹ̀

25 Ọjọ́ méje kọjá ti Olúwa ti lu odò Naili.

Veja também