Publicidade

Gênesis 15

Májẹ̀Ọlọ́run pẹ̀Abramu

1 Lẹ́yìn èyí, ̀rọ̀ Olúwa tọ Abramu lójú ìran ,

"Abramu ṣe bẹ̀.

Èmi ni ààbò rẹ,

Èmi ni èrè ńlá rẹ."

2 Ṣùgbọ́n Abramu , "Olúwa Olódùmarè, ni ìwọ yóò fi fún mi níwọ̀n ìgbà èmi bímọ, Elieseri ará Damasku ni yóò jogún mi," 3 Abramu tún tẹ̀síwájú , "Ìwọ fún mi ọmọ, nítorí náà ẹrú nínú ilé mi ni yóò jẹ́ àrólé mi."

4 15.4: Gẹ 17.16,21; 18.10; 21.2. ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ ́ , "Ọkùnrin yìí kọ́ ni yóò jẹ́ àrólé rẹ ṣe ọmọ ìwọ fúnra rẹ̀ ni yóò jẹ́ àrólé rẹ." 5 15.5: Ro 4.18; Hb 11.12.Olúwa Abramu jáde ìta ó fún un , "Gbé ojú sókè ̀run o ka àwọn ìràwọ̀ ó ṣe ìwọ le è wọ́n." Ó fun un , "Nítorí náà, báyìí ni irú-ọmọ rẹ yóò ."

6 15.6: Ro 4.3; Ga 3.6; Jk 2.23. Abramu gba Olúwa gbọ́, a á òdodo fún un.

7 Ó tún fún un , "Èmi ni Olúwa ó jáde láti Uri ti Kaldea láti fún ilẹ̀ yìí láti jogún."

8 Ṣùgbọ́n Abramu , "Olúwa Olódùmarè, báwo ni mo ṣe mọ̀ ilẹ̀ náà yóò jẹ́ ohun ìní mi?"

9 Nítorí náà, Olúwa fún un , "abo màlúù, ewúrẹ́ àti àgbò ọlọ́dún mẹ́ta mẹ́ta , àti àdàbà kan àti ọmọ ẹyẹlé kan."

10 Abramu gbogbo nǹkan wọ̀nyí , ó wọ́n méjì méjì, ó fi ̀èkínní kọjú èkejì, ṣùgbọ́n la àwọn ẹyẹ tiwọn. 11 Àwọn ẹyẹ igún ń sórí òkú ẹran náà, Abramu ń wọn.

12 15.12: Jb 4.13,14. oòrùn ti ń wọ̀, Abramu sùn lọ fọnfọn, òkùnkùn biribiri ó kún fún ̀ó. 13 15.13: Ek 1.1-14; Ap 7.6.15.13-14: Ek 12.40,41; Ap 7.7.Nígbà náà ni Olúwa fún Abramu , "Mọ èyí dájú , irú-ọmọ rẹ yóò ṣe àtìpó ilẹ̀ àjèjì, wọn ó sọ wọn di ẹrú, wọn ó pọ́n wọn lójú fún irinwó (400) ọdún. 14 Ṣùgbọ́n orílẹ̀-èdè náà wọn yóò máa sìn, ni èmi ó lẹ́jọ́, lẹ́yìn náà ni wọn ó jáde pẹ̀ọrọ̀ púpọ̀. 15 Ṣùgbọ́n ìwọ yóò tọ àwọn baba rẹ lọ ni àlàáfíà, bẹ́̀ ni ìwọ yóò di arúgbó a gbé sin. 16 ìran kẹrin àwọn ìran rẹ yóò padà ibi. Nítorí ̀ṣẹ̀ àwọn ará Amori ì ì kún òsùwọ̀n."

17 Nígbà oòrùn wọ̀ ilẹ̀ ṣú, ìkòkò iná ń ṣèéfín àti ọwọ́ iná ń kọjá láàrín ̀ẹran náà. 18 15.18: Gẹ 17.2,7,9-14,21.ọjọ́ náà gan an ni Olúwa májẹ̀pẹ̀Abramu, ó , "Àwọn ìran rẹ ni èmi yóò fi ilẹ̀ yìí fún, láti odò Ejibiti odò ńlá Eufurate: 19 ilẹ̀ àwọn ará Keni, àti ti ará Kenissiti, àti ará Kadmoni, 20 àti ti ará Hiti, àti ti ará Peresi, àti ti ará Refaimu. 21 Àti ti ará Amori, àti ti ará Kenaani, àti ti ará Girgaṣi àti ti ará Jebusi."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-