Publicidade

Gênesis 18

Àwọn àlejò mẹ́ta

1 Olúwa farahan Abrahamu nítòsí àwọn igi ńlá Mamre, ó ti jókòó ẹnu-ọ̀àgọ́ rẹ̀, nígbà ọjọ́-kanrí oòrùn . 2 18.2: Hb 13.2.Abrahamu gbójú sókè, ó àwọn ọkùnrin mẹ́ta wọn dúró nítòsí rẹ̀. Nígbà ó wọn, ó sáré láti lọ pàdé wọn, ó tẹríba ó ti ń wọn.

3 Ó , "mo ojúrere yín Olúwa mi, ṣe lọ láì sọ́dọ̀ ìránṣẹ́ yín. 4 jẹ́ a bu omi díẹ̀ ̀yin ó wẹ ẹsẹ̀ yín, sinmi lábẹ́ igi níhìn-ín. 5 jẹ́ n oúnjẹ fún un yín, ̀yin ó jẹ, ara yín, si tẹ̀síwájú ̀yín, nígbà ti ̀dọ̀ ìránṣẹ́ yín."

Wọn "Ó dára."

6 Abrahamu yára tọ Sara aya rẹ̀ lọ nínú àgọ́, ó , "Tètè òsùwọ̀n ìyẹ̀fun dáradára mẹ́ta o ó pọ̀, o ṣe oúnjẹ."

7 Abrahamu tún sáré lọ ibi agbo ẹran, ó ọmọ màlúù kan fún ìránṣẹ́ rẹ̀, ìránṣẹ́ náà tètè ṣè é. 8 Ó wàrà àti mílíìkì àti màlúù ó ti pèsè, ó gbé síwájú wọn. Ó dúró nítòsí wọn lábẹ́ igi wọn ti ń jẹ ́.

9 Wọn béèrè , "Sara aya rẹ ń kọ́?"

Ó dáhùn , "Ó nínú àgọ́."

10 18.10: Ro 9.9. Nígbà náà ni Olúwa fún un , "Èmi yóò tún padà tọ̀ ́ nítòótọ́ ìwòyí àmọ́dún; Sara aya rẹ yóò ọmọkùnrin kan."

Sara ń dẹtí gbọ́ láti ẹnu-ọ̀àgọ́ ó lẹ́yìn ọkùnrin náà. 11 Abrahamu àti Sara ti di arúgbó, Sara ti kọjá àsìkò ìbímọ. 12 18.12: 1Pt 3.6.Nítorí náà, Sara rẹ́rìn-ín nínú ara rẹ̀ ó ti ń ó lọ́kàn rẹ̀ , "Lẹ́yìn ìgbà mo ti di arúgbó tán olúwa mi pẹ̀ti gbó jọ̀kújọ̀, èmi yóò ha tún bímọ?"

13 Nígbà náà ni Olúwa fún Abrahamu , "Kín Sara fi rẹ́rìn-ín ó , Èmi yóò ha bímọ nítòótọ́, nígbà mo di ẹni ogbó tán?14 18.14: Mt 19.26; Mk 10.27; Lk 1.37; Ro 9.9.Ǹjẹ́ ohunkóhun ó ṣòro fún Olúwa? Èmi ó padà tọ̀ ́ ìwòyí àmọ́dún, Sara yóò ọmọkùnrin."

15 ̀ba Sara, ó sẹ́ òun rẹ́rìn-ín.

Ṣùgbọ́n Olúwa fún un , "Dájúdájú ìwọ rẹ́rìn-ín."

Abrahamu bẹ Olúwa nítorí Sodomu

16 Nígbà àwọn ọkùnrin náà dìde láti máa lọ, wọn kọjú ̀Sodomu, Abrahamu sìn wọ́n ̀. 17 Nígbà náà ni Olúwa , "Ǹjẹ́ èmi yóò ha pa ohun mo fẹ́ ṣe mọ́ fún Abrahamu ? 18 18.18: Gẹ 12.3; Ap 3.25; Ga 3.8.Dájúdájú Abrahamu yóò à di orílẹ̀-èdè ńlá àti alágbára, àti gbogbo orílẹ̀-èdè ayé ni a ó bùkún fún nípasẹ̀ rẹ̀. 19 Nítorí èmi ti yàn án láti kọ́ àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ará ilé rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀, láti máa pa ̀Olúwa mọ nípa ṣíṣe olóòtítọ́ àti olódodo: Olúwa le è ìlérí rẹ̀ fún Abrahamu ṣẹ."

20 Olúwa , igbe Sodomu àti Gomorra pọ̀ púpọ̀ àti ̀ṣẹ̀ wọn burú jọjọ. 21 "Èmi yóò sọ̀kalẹ̀ síbẹ̀ láti ṣe ìwádìí igbe ó etí ìgbọ́ mi nípa wọn, èmi mọ òtítọ́ ó níbẹ̀."

22 Àwọn ọkùnrin náà padà, wọ́n ń lọ ìhà Sodomu. Ṣùgbọ́n Abrahamu dúró níbẹ̀ níwájú Olúwa. 23 Nígbà náà ni Abrahamu súnmọ́ ̀dọ̀ Olúwa, ó , "Ìwọ yóò ha pa olódodo ènìyàn àti ènìyàn búburú run papọ̀ ?" 24 "ó ṣe ìwọ àádọ́ta olódodo nínú ìlú náà, ìwọ yóò ha run ún, ìwọ yóò ha ìlú náà nítorí àwọn àádọ́ta olódodo ó nínú rẹ̀ náà? 25 jẹ́ bẹ́̀! Dájúdájú ìwọ yóò ṣe ohun ó jọ bẹ́̀, láti pa olódodo pẹ̀àwọn ènìyàn rere àti àwọn ènìyàn búburú. Dájúdájú, ìwọ yóò ṣe èyí ó tọ́ bi?"

26 Olúwa , "mo àádọ́ta olódodo ìlú Sodomu, èmi yóò ìlú náà nítorí tiwọn."

27 Abrahamu tún tẹ̀síwájú , "ó nísinsin yìí, níwọ̀n èmi ti ìgboyà láti bẹ̀rẹ̀ sọ̀rọ̀ níwájú Olúwa, èmi ẹni í ṣe erùpẹ̀ àti eérú, 28 ó ṣe pe olódodo márùndínláàádọ́ta ni ó nínú ìlú, ìwọ yóò ha pa ìlú náà run nítorí ènìyàn márùn-ún ?"

Olúwa dáhùn , "Èmi yóò pa ìlú náà run mo olódodo márùndínláàádọ́ta nínú rẹ̀."

29 Òun tún lẹ́̀kan si , "ó ṣe ogójì ni ń kọ́?"

Olúwa tún , "Èmi yóò pa ìlú náà run mo olódodo ogójì nínú rẹ̀."

30 Abrahamu tún bẹ Olúwa , "Olúwa ṣe bínú, ṣùgbọ́n èmi yóò sọ̀rọ̀. ó ṣe ọgbọ̀n ni a níbẹ̀ ń kọ́?"

Olúwa dáhùn , "ọgbọ̀n, èmi yóò pa ìlú run."

31 Abrahamu , "Níwọ́n mo ti ìgboyà láti Olúwa sọ̀rọ̀ báyìí, jẹ́ n tẹ̀síwájú. o ṣe olódodo ogún péré ni ó nínú ìlú náà ń kọ́?"

Olúwa dáhùn , "Èmi yóò pa á run nítorí ogún ènìyàn náà."

32 Abrahamu , "Jọ̀wọ́ ṣe bínú Olúwa. Jẹ́ ń béèrè lẹ́̀kan si. ó ṣe ènìyàn mẹ́wàá ni ó jẹ́ olódodo ń kọ́?"

Olúwa , "Nítorí ènìyàn mẹ́wàá náà, èmi yóò pa á run."

33 Olúwa tirẹ̀ lọ, nígbà ó Abrahamu sọ̀rọ̀ tán, Abrahamu padà sílé.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-