Publicidade

Gênesis 27

Isaaki súre fún Jakọbu

1 Nígbà ti Isaaki di arúgbó, ojú rẹ̀ ti di bàìbàì bẹ́̀ le ríran. Ó pe Esau àkọ́rẹ̀, ó fún un , "Ọmọ mi."

Esau dáhùn , "Èmi nìyí."

2 Isaaki , "Nísinsin yìí mo di arúgbó, èmi mọ ọjọ́ èmi yóò . 3 Nítorí náà, ohun èlò ọdẹ rẹ, apó àti ọrún, nísinsin yìí o lọ pa ẹran fún mi nínú igbó. 4 o ṣe ẹran àdídùn fún mi, irú èyí mo fẹ́ràn, o gbe fún mi n jẹ, n súre fún n ."

5 Ṣùgbọ́n Rebeka ń fetí léko gbọ́ nígbà Isaaki ń Esau ọmọ rẹ̀ sọ̀rọ̀. Nítorí náà, nígbà ti Esau ti ṣe ọdẹ lọ sínú igbó, 6 Rebeka sọ fún Jakọbu ọmọ rẹ̀ , "ó, mo gbọ́ baba rẹ ń fún Esau ̀gbọ́n rẹ , 7 Pa ẹran fún mi , o ṣe oúnjẹ àdídùn fún mi láti jẹ, n ba à le súre fún níwájú Olúwa èmi .8 Nísinsin yìí ọmọ mi, gbọ́ tèmi, o ṣe ohun èmi yóò fún . 9 Lọ sínú agbo ẹran, o ọmọ ewúrẹ́ méjì, ó ṣe oúnjẹ àdídùn fún baba rẹ, irú èyí ó fẹ́ràn dáradára. 10 Ìwọ yóò gbé e tọ baba rẹ lọ, òun ba à jẹ ́, ó súre fún , ó ."

11 Jakọbu fún Rebeka ìyá rẹ̀ , "Ṣùgbọ́n Esau ̀gbọ́n mi jẹ́ ènìyàn onírun lára, bẹ́̀ alára ̀bọ̀rọ́ ni èmi, 12 baba mi fọwọ́ kàn mi ń kọ́? Èmi yóò jọ ẹlẹ́tàn lójú rẹ̀, dípò ó súre fún mi, èmi yóò ègún sórí ara mi."

13 Ìyá rẹ̀ fun un , "Ọmọ mi jẹ́ ègún náà sórí mi, à ṣe ohun mo , o wọn fún mi."

14 Jakọbu ṣe ohun gbogbo ìyá rẹ̀ fun un, Rebeka ṣe oúnjẹ àdídùn náà, irú èyí Isaaki fẹ́ràn. 15 Nígbà náà ni Rebeka èyí ó dára nínú aṣọ Esau ọmọ rẹ̀ àgbà ó nínú ilé Rebeka, ó fi wọ Jakọbu ọmọ rẹ̀ àbúrò. 16 Ó fi awọ ewúrẹ́ wọ̀n-ọn-nì bo ọwọ́ àti ibi ̀bọ̀rọ́ ọrùn. 17 Nígbà náà ni ó gbé ẹran dídùn náà àti oúnjẹ ó ti Jakọbu ọmọ rẹ̀ lọ́wọ́.

18 Jakọbu wọlé lọ ̀dọ̀ baba rẹ̀ ó , "Baba mi."

Baba rẹ dáhùn , "Èmi nìyí, ìwọ ta ni, ọmọ mi?"

19 Jakọbu fèsì , "Èmi ni Esau àkọ́rẹ, èmi ti ṣe gẹ́gẹ́ ìwọ ti sọ fún mi, jọ̀wọ́ dìde jókòó, o jẹ nínú ẹran igbó mi mo ti , o ba à le súre fún mi pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ."

20 Isaaki tún béèrè , "Ọmọ mi, báwo ni ó ṣe tètè bẹ́̀?"

Jakọbu tún dáhùn , "Olúwa Ọlọ́run rẹ fún mi pa."

21 Nígbà náà ni Isaaki fún Jakọbu , "Súnmọ́ mi, n le è fọwọ́ kàn ́, n mọ̀ bóyá Esau ọmọ mi ni nítòótọ́ tàbí òun kọ́."

22 Jakọbu súnmọ́ Isaaki baba rẹ̀. Isaaki fọwọ́ kàn án, ó , "Ohùn ni ohùn Jakọbu; ṣùgbọ́n ọwọ́ ni ọwọ́ Esau." 23 Jakọbu mọ̀ nítorí ọwọ́ rẹ̀ irun i ti Esau arákùnrin rẹ, nítorí náà, ó súre fún un 24 ó bi í léèrè , "Ǹjẹ́ ìwọ ni Esau ọmọ mi ni tòótọ́?"

Jakọbu dáhùn , "Èmi ni."

25 Nígbà náà ni Isaaki , "Gbé ẹran igbó náà súnmọ́ ̀dọ̀ mi, èmi ó jẹ ́, èmi súre fún láti inú ọkàn mi ."

Jakọbu gbé e ó jẹ ́, ó tún fún un wáìnì, ó un pẹ̀. 26 Nígbà náà ni Isaaki baba rẹ̀ fun un , "Súnmọ́ mi, ọmọ mi, o fẹnukò ẹnu."

27 Ó súnmọ́ ọn, ó fẹnukò ó ẹnu. Nígbà Isaaki gbọ́ òórùn aṣọ rẹ̀, ó súre fún un ó ,

"ó òórùn ọmọ mi

dàbí òórùn oko

Olúwa ti bùkún.

28 Ọlọ́run ó fún nínú ìrì ̀run

àti nínú ̀ilẹ̀

àti ̀pọ̀lọpọ̀ ọkà àti wáìnì tuntun.

29 àwọn orílẹ̀-èdè ó máa sìn ́,

àwọn ènìyàn máa tẹríba fún ,

máa ṣe olórí àwọn arákùnrin rẹ,

àwọn iyèkan rẹ máa wólẹ̀ fún

Fífibú ni àwọn ẹni fi ́ ,

ìbùkún ni fún àwọn ẹni ó súre fún ."

30 Isaaki ti súre tán Jakọbu ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde kúrò ̀dọ̀ baba rẹ̀ ni Esau ti oko ọdẹ . 31 Òun pẹ̀ṣe ẹran dídùn, ó gbé e tọ baba rẹ̀ , ó fún un , "Baba mi, dìde jókòó, o jẹ nínú ẹran igbó mo ti ṣè, o súre fún mi."

32 Isaaki baba rẹ̀ bi í , "Ìwọ ta ni?"

Ó dáhùn , "Èmi Esau, àkọ́rẹ ni."

33 Nígbà náà ni Isaaki wárìrì gidigidi, ó , "Ta ni ẹni náà, ó ti pa ẹran igbó ó ti gbe fún mi, mo ti jẹ ́ ó ? Mo ti súre fún un, ó dájúdájú a ó bùkún un!"

34 Nígbà Esau gbọ́ ̀rọ̀ baba rẹ̀, ó , ó bẹ̀rẹ̀ sọkún kíkorò, ó fún baba rẹ̀ , "Baba mi súre fún èmi náà, àní fún èmi náà pẹ̀."

35 Ṣùgbọ́n Isaaki , "Àbúrò rẹ ti fi ̀tàn , ó ti gba ìbùkún rẹ lọ."

36 Esau , "Lásán ni a pe orúkọ rẹ̀ Jakọbu ? ìgbà méjì yìí ni ó ti tàn jẹ: àkọ́kọ́, ó gba ogún ìbí mi, nísinsin yìí, ó tún gba ìbùkún mi!" O béèrè , "Ṣe o fi ìre kankan sílẹ̀ fun mi ni?"

37 Isaaki Esau lóhùn , "Mo ti fi ṣe olórí rẹ àti àwọn ìbátan rẹ ni mo fi ṣe ìránṣẹ́ fún un, àti ọkà àti wáìnì ni mo ti fi e lọ́wọ́ lọ́pọ̀lọ́pọ̀, ni ó tún ǹ tún fún báyìí ọmọ mi?"

38 Esau fún baba rẹ̀ , "Ṣe ìre kan ṣoṣo ni ìwọ lẹ́nu ni baba mi? Súre fún èmi náà, baba mi." Esau sọkún kíkankíkan.

39 Isaaki baba rẹ̀ a lóhùn ,

"Ibùjókòó rẹ

yóò jìnnà ̀ilẹ̀,

àti ibi ìrì ̀run láti òkè .

40 Nípa idà rẹ ni ìwọ yóò máa gbé,

ìwọ yóò máa sin àbúrò rẹ,

ṣùgbọ́n ìkẹyìn, nígbà ìwọ di alágbára

ìwọ yóò àjàgà rẹ̀

kúrò lọ́rùn rẹ."

Jakọbu sálọ ̀dọ̀ Labani

41 Esau kórìíra Jakọbu nítorí ìre baba rẹ̀ fún un, ó fún ara rẹ̀ , "Baba mi à ti fẹ́rẹ , nígbà náà ni èmi ó pa Jakọbu, arákùnrin mi."

42 Nígbà Rebeka gbọ́ ohun Esau àkọ́rẹ̀ , ó ránṣẹ́ Jakọbu, ó fun un , "Esau ̀gbọ́n rẹ ń tu ara rẹ̀ nínú pẹ̀èrò à ti pa ́. 43 Nítorí náà ọmọ mi, ṣe ohun èmi yóò sọ fún , sálọ sọ́dọ̀ Labani ̀gbọ́n mi Harani. 44 Jókòó ibẹ̀ títí di ìgbà ìbínú ̀gbọ́n rẹ yóò fi rọ̀. 45 Nígbà ̀gbọ́n rẹ bínú mọ́, ó ti gbàgbé ohun ìwọ ṣe i, èmí ó ránṣẹ́ láti padà . Èéṣe èmi ó fi pàdánù ̀yin méjèèjì ọjọ́ kan náà?"

46 Nígbà náà ni Rebeka fún Isaaki , "Ayé mi nítorí àwọn ọmọbìnrin Hiti wọ̀nyí. Jakọbu fẹ́ ̀kan nínú àwọn ọmọbìnrin Hiti wọ̀nyí, ó kúkú sàn n láààyè."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-