Pular para o conteúdo
Publicidade

Gênesis 38

Juda àti Tamari

1 àkókò náà, Juda lọ kúrò lọ́dọ̀ àwọn arákùnrin rẹ̀ láti lọ dúró lọ́dọ̀ ọkùnrin ará Adullamu kan ń jẹ́ Hira. 2 Juda pàdé ọmọbìnrin Kenaani kan níbẹ̀ ẹni ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ṣua. Ó fi ṣe aya, ó a lòpọ̀; 3 ó lóyún, ó ọmọkùnrin kan, ó sọ orúkọ rẹ̀ Eri. 4 Ó tún lóyún, ó ọmọkùnrin, ó sọ orúkọ rẹ̀ Onani. 5 Ó tún ọmọkùnrin mìíràn, ó pe orúkọ rẹ̀ Ṣela. Kesibu ni ó nígbà ó i.

6 Juda fẹ́ aya fún Eri, àkọ́rẹ̀, orúkọ aya náà ni Tamari. 7 Ṣùgbọ́n Eri àkọ́Juda ṣe ènìyàn búburú níwájú Olúwa, Ọlọ́run pa á.

8 Nígbà náà ni Juda fún Onani, "aya arákùnrin rẹ lòpọ̀, o ṣe ojúṣe rẹ fun un gẹ́gẹ́ àbúrò ọkọ, ó ba à le ọmọ fún un orúkọ arákùnrin rẹ." 9 Ṣùgbọ́n Onani mọ̀ àwọn ọmọ náà yóò jẹ́ ti òun, nítorí náà ni gbogbo ìgbà ó wọlé tọ aya arákùnrin rẹ̀ lọ, ilẹ̀ ni ó ń da nǹkan ọkùnrin rẹ̀ , ó a bímọ fún arákùnrin rẹ̀. 10 Ohun ó ń ṣe yìí burú lójú Olúwa, ó pa òun náà pẹ̀.

11 Nígbà náà ni Juda fún Tamari, ìyàwó ọmọ rẹ̀ , "Lọ máa gbé opó ilé baba rẹ, títí Ṣela yóò fi dàgbà ó lérò òun náà àwọn arákùnrin rẹ̀ tókù." Nígbà náà ni Tamari ń lọ gbé ilé baba rẹ̀.

12 Lẹ́yìn ìgbà pípẹ́, ìyàwó Juda, ọmọbìnrin Ṣua , nígbà ọjọ́ ̀fọ̀ Juda , ó gòkè lọ Timna, ̀dọ̀ àwọn ń a rẹ́run àgùntàn rẹ̀, Hira ará Adullamu í ṣe ̀rẹ́ rẹ̀ a lọ.

13 Nígbà ẹnìkan sọ fún Tamari , "Baba ọkọ ̀ rẹ̀ ̀àjò rẹ̀ Timna láti rẹ́run àgùntàn rẹ̀." 14 Ó bọ́ aṣọ opó rẹ̀, ó fi ìbòjú bo ojú ara rẹ̀ wọn ba à mọ̀ ́n. Ó jókòó ẹnu-bodè Enaimu, èyí ó ̀Timna. Nítorí ó i , ó tilẹ̀ jẹ́ Ṣela ti dàgbà, síbẹ̀, a fi òun fún un gẹ́gẹ́ aya.

15 Nígbà Juda i, ó panṣágà ni, nítorí ó ti bo ojú rẹ̀. 16 Láìmọ̀ , aya ọmọ òun í ṣe, ó tọ̀ ́ ̀̀, ó , "èmi ó wọlé tọ̀ ́."

Òun , "Kín ni ìwọ yóò fi fún mi ìwọ wọlé tọ̀ ."

17 Ó , "Èmi yóò fi ọmọ ewúrẹ́ kan ránṣẹ́ láti inú agbo ẹran."

Obìnrin náà dáhùn , "Ṣé ìwọ yóò fún mi ohun kan gẹ́gẹ́ ̀títí ìwọ yóò fi fi ránṣẹ́?"

18 Juda bi í , "̀wo ni n fún ?"

Ó dáhùn , "Èdìdì ìdámọ̀ okùn àti ̀ìtìlẹ̀ rẹ ti ń bẹ ọwọ́ rẹ." Ó wọn fún un, ó sùn í, obìnrin náà lóyún nípasẹ̀ rẹ̀. 19 Lẹ́yìn ìgbà ó lọ, ó bọ́ ìbòjú ojú rẹ̀, ó tún wọ aṣọ opó rẹ̀ padà.

20 Juda rán ọmọ ewúrẹ́ náà láti ọwọ́ ̀rẹ́ rẹ̀, ará Adullamu náà lọ láti gba ògo n lọ́wọ́ obìnrin náà. Ṣùgbọ́n wọn obìnrin náà níbẹ̀. 21 Ó béèrè lọ́wọ́ àwọn ènìyàn àdúgbò náà , "Níbo ni alágbèrè ojúbọ òrìṣà ó etí ̀Enaimu ?"

Wọ́n a lóhùn , "alágbèrè ojúbọ òrìṣà kankan níbí."

22 Ó padà lọ sọ́dọ̀ Juda ó fún un , "Èmí i, à ti àwọn aládùúgbò ibẹ̀ sọ alágbèrè ojúbọ òrìṣà kankan níbẹ̀."

23 Nígbà náà ni Juda , "Jẹ́ ó máa àwọn ohun ó lọ́wọ́ rẹ̀ lọ ṣe bẹ́̀ a ó di ẹlẹ́. Mo à fi ọmọ ewúrẹ́ ránṣẹ́ i, ṣùgbọ́n ìwọ òun."

24 Lẹ́yìn nǹkan oṣù mẹ́ta, wọn sọ fún Juda , "Tamari aya ọmọ rẹ̀ ṣe àgbèrè, ó ti lóyún."

Juda , "un jáde, iná sun ún."

25 wọ́n ti ń un jáde, ó ránṣẹ́ baba ọkọ rẹ̀ , "Ọkùnrin ó ni àwọn nǹkan wọ̀nyí ni ó fún mi lóyún. ó, bóyá o mọ ẹni ó ni èdìdì ìdámọ̀, okùn àti ̀ìtìlẹ̀ wọ̀nyí."

26 Juda wọn mọ̀, ó , "O ṣe olódodo lọ, níwọ̀n ìgbà n fi fún Ṣela ọmọ mi." a lòpọ̀ mọ́ láti ọjọ́ náà.

27 Nígbà àsìkò ìbímọ rẹ̀ . Ìbejì ọkùnrin ni ó . 28 ó ti ń bímọ, ̀kan nínú àwọn ọmọ náà na ọwọ́ jáde; agbẹ̀so okùn òdòdó mọ́ ọmọ náà ọrùn ọwọ́. Ó , "Èyí ni o kọ́kọ́ jáde." 29 Ṣùgbọ́n nígbà ó fa ọwọ́ rẹ̀ padà, èkejì rẹ̀ jáde. Tamari , "Níbo ni ìwọ ti ?" Ó pe orúkọ rẹ̀ Peresi. 30 Nígbà náà ni èkejì a ti so okùn olódòdó mọ́ lọ́rùn ọwọ́ jáde, wọ́n pe orúkọ rẹ̀ ni Sera.

Veja também