Pular para o conteúdo
Publicidade

Gênesis 47

1 Josẹfu lọ sọ fún Farao , "Baba mi àti àwọn arákùnrin mi, pẹ̀agbo ẹran, agbo màlúù àti ohun gbogbo wọ́n , ti láti ilẹ̀ Kenaani, wọ́n ti ilẹ̀ Goṣeni báyìí." 2 Ó yan márùn-ún àwọn arákùnrin rẹ́, ó fi wọ́n han Farao.

3 Farao béèrè lọ́wọ́ àwọn arákùnrin rẹ̀ , "ni iṣẹ́ yín?"

Wọ́n fèsì , "Darandaran ni àwọn ìránṣẹ́ rẹ, gẹ́gẹ́ àwọn baba wa ti jẹ́ darandaran." 4 Wọ́n tún sọ fun un síwájú i , "A láti gbé ìhín yìí fún ìgbà díẹ̀ nítorí ìyàn náà púpọ̀ ilẹ̀ Kenaani, àwọn ohun ̀sìn àwa ìránṣẹ́ rẹ ewéko jẹ. Nítorí náà jọ̀wọ́ ṣàì jẹ́ àwọn ìránṣẹ́ rẹ tẹ̀ilẹ̀ Goṣeni."

5 Farao fún Josẹfu , "Baba rẹ àti àwọn arákùnrin rẹ tọ̀ ́ , 6 ilẹ̀ Ejibiti nìyí níwájú rẹ, àwọn arákùnrin rẹ tẹ̀ibi ó dára nínú ilẹ̀ náà. Jẹ́ wọn máa gbé Goṣeni. o mọ ẹnikẹ́ni nínú wọn ó ̀bùn ìtọ́ẹran, fi wọ́n ṣe olùtọ́ẹran ̀sìn mi."

7 Nígbà náà ni Josẹfu Jakọbu baba rẹ̀ wọlé iwájú Farao. Lẹ́yìn ìgbà Jakọbu súre fún Farao tán. 8 Farao béèrè lọ́wọ́ Jakọbu , "Ọmọ ọdún mélòó ni ́?"

9 Jakọbu Farao lóhùn, "Ọdún ìrìnàjò ayé mi jẹ́ àádóje, ọjọ́ mi pọ̀, ó kún fún wàhálà, síbẹ̀ ì ì ti àwọn baba mi." 10 Nígbà náà ni Jakọbu tún súre fún Farao, ó jáde lọ kúrò níwájú rẹ̀.

11 Josẹfu fi baba rẹ̀ àti àwọn arákùnrin rẹ̀ ilẹ̀ Ejibiti, ó fún wọn ohun ìní ibi ó dára ilẹ̀ náà, agbègbè Ramesesi Farao ti pàṣẹ. 12 Josẹfu pèsè oúnjẹ fún baba rẹ̀ àti àwọn arákùnrin rẹ̀ àti gbogbo ìdílé baba rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi iye àwọn ọmọ wọn.

Josẹfu àti ìyàn ilẹ̀ Ejibiti

13 Ṣùgbọ́n oúnjẹ gbogbo ilẹ̀ náà nítorí ìyàn náà púpọ̀ bẹ́̀ ilẹ̀ Ejibiti àti ilẹ̀ Kenaani gbẹ nítorí ìyàn náà. 14 Josẹfu gba gbogbo owó ó ilẹ̀ Ejibiti àti Kenaani ìpààrọ̀ fún ti ọkà wọn ń , ó owó náà ààfin Farao. 15 Nígbà owó wọn tán pátápátá Ejibiti àti Kenaani, gbogbo Ejibiti Josẹfu, wọ́n , "Fún wa oúnjẹ, èéṣe a ó fi ojú rẹ? Gbogbo owó wa ni a ti tán."

16 Josẹfu , "àwọn ẹran ̀sìn yín , èmi yóò fún un yín oúnjẹ ìpààrọ̀ fún ẹran ̀sìn yín, níwọ̀n owó yín ti tan." 17 Nítorí náà wọ́n àwọn ẹran ̀sìn wọn tọ Josẹfu , ó fún wọn oúnjẹ ìpààrọ̀ fún ẹṣin, àgùntàn, ewúrẹ́, màlúù àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn. Ó wọn la ọdún náà , ó ń fún wọn oúnjẹ ìpààrọ̀ fún ẹran ̀sìn wọn.

18 Nígbà ọdún náà parí, wọn padà tọ̀ ́ ọdún ó tẹ̀, wọn , "A le fi pamọ́ fun olúwa wa níwọ̀n owó wa ti tan gbogbo ẹran ̀sìn wa ti di tirẹ̀ , ohunkóhun tókù fún olúwa wa ṣe ara wa àti ilẹ̀ wa. 19 Èéṣe àwa yóò fi parun lójú rẹ, ra àwa tìkára wa àti ilẹ̀ wa ìpààrọ̀ fún oúnjẹ, àwa àti ilẹ̀ wa yóò nínú ìgbèkùn Farao. Fún wa ni oúnjẹ àwa ó ba à , ilẹ̀ wa ba à di ahoro."

20 Nítorí náà Josẹfu ra gbogbo ilẹ̀ ó Ejibiti fún Farao, ẹnìkan ó ṣẹ́Ejibiti ta ilẹ̀ tirẹ̀ nítorí ìyàn náà fún wọn. Gbogbo ilẹ̀ náà di ti Farao, 21 Josẹfu sọ gbogbo ará Ejibiti di ẹrú láti igun kan èkejì. 22 Ṣùgbọ́n ṣá, ra ilẹ̀ àwọn àlùfáà, nítorí wọ́n ń gba ìpín oúnjẹ lọ́wọ́ Farao, wọn oúnjẹ ó láti inú ìpín Farao ń fún wọn. Ìdí nìyí wọn fi ta ilẹ̀ wọn.

23 Josẹfu fún àwọn ènìyàn náà , "Níwọ́n ìgbà mo ti ra ̀yin àti ilẹ̀ yín tan lónìí fún Farao, irúgbìn rèé, lọ gbìn ín ilẹ̀ náà. 24 Ṣùgbọ́n nígbà ìre oko náà jáde, ó ìdákan nínú ìdámárùn-ún rẹ̀ fún Farao. le pa ìdámẹ́rin tókù mọ́ fún ara yín àti ìdílé yín àti àwọn ọmọ yín."

25 Wọ́n á lóhùn , "O ti gbà , ǹjẹ́ a ojúrere níwájú olúwa wa, àwa yóò di ẹrú Farao."

26 Nítorí náà Josẹfu sọ ́ di òfin nípa ̀rọ̀ ilẹ̀ ni Ejibiti, ó bẹ́̀ di òní olónìí , ìdákan nínú ìdámárùn-ún ìre oko jẹ́ ti Farao, ilẹ̀ àwọn àlùfáà nìkan ni di ti Farao.

27 Àwọn ará Israẹli tẹ̀Ejibiti agbègbè Goṣeni. Wọ́n ohun ìní fún ara wọn, wọ́n i bẹ́̀ wọ́n pọ̀ si gidigidi iye.

28 Jakọbu gbé Ejibiti fún ọdún mẹ́tàdínlógún iye ọdún ọjọ́ ayé rẹ̀ jẹ́ ẹẹ́tàdínlàádọ́jọ (147). 29 47.29,30: Gẹ 49.29-32; 50.6.Nígbà àkókò ń súnmọ́ etílé fún Israẹli láti , ó pe Josẹfu, ọmọ rẹ̀, ó fún un , "mo ojúrere ni ojú rẹ̀ fi ọwọ́ rẹ abẹ́ itan mi, o ṣe ìlérí ìwọ yóò fi àánú àti òtítọ́ hàn mi. ṣe sin òkú mi ilẹ̀ Ejibiti. 30 Ṣùgbọ́n, nígbà mo sinmi pẹ̀àwọn baba mi, gbé jáde kúrò Ejibiti o sin ibi wọ́n sin àwọn baba mi ."

Josẹfu dáhùn , "Èmi ó ṣe ìwọ ti ."

31 Jakọbu , "Búra fún mi," Josẹfu búra fún un. Israẹli tẹ orí rẹ̀ ba, ó ti sinmi orí ibùsùn rẹ̀.

Veja também