Pular para o conteúdo
Publicidade

Gênesis 9

4 9.4: Le 7.26,27; 17.10-14; De 12.16,23. "Ṣùgbọ́n ̀yin gbọdọ̀ jẹ ẹran tòun-tẹ̀jẹ̀ rẹ̀. 5 Nítòótọ́ ̀jẹ̀ yín, àní ̀yín, ni èmi yóò béèrè; lọ́wọ́ gbogbo ẹranko ni èmí yóò béèrè rẹ̀, àti lọ́wọ́ ènìyàn, lọ́wọ́ arákùnrin olúkúlùkù ènìyàn ni èmi yóò béèrè ̀ènìyàn.

6 9.6: Ek 20.13; Gẹ 1.26. "Ẹnikẹ́ni ó ta ̀jẹ̀ ènìyàn sílẹ̀,

láti ọwọ́ ènìyàn ni a ó gbà ta ̀jẹ̀ rẹ̀ sílẹ̀.

Nítorí àwòrán Ọlọ́run

ni Ọlọ́run ènìyàn.

Veja também