Publicidade

Josué 4

1 Nígbà gbogbo orílẹ̀-èdè náà kọjá nínú odò Jordani tan, Olúwa sọ fún Joṣua , 2 "Yan ọkùnrin méjìlá nínú àwọn ènìyàn, ẹnìkan nínú ̀kọ̀̀kan, 3 o pàṣẹ fún wọn , gbé òkúta méjìlá láti àárín odò Jordani ibi àwọn àlùfáà dúró , wọn kọjá, gbé wọn ibi ̀yin yóò sùn alẹ́ yìí.’ "

4 Bẹ́̀ ni Joṣua pe àwọn ọkùnrin méjìlá ó ti yàn nínú àwọn ọmọ Israẹli, ẹnìkan nínú ̀kọ̀̀kan, 5 ó fún wọn , "kọjá lọ iwájú àpótí ̀Olúwa Ọlọ́run yín àárín odò Jordani. olúkúlùkù yín gbé òkúta kọ̀̀kan èjìká a rẹ̀, gẹ́gẹ́ iye ̀àwọn ọmọ Israẹli, 6 ó jẹ́ àmì láàrín yín. ọjọ́ iwájú, nígbà àwọn ọmọ yín béèrè lọ́wọ́ yín , ni òkúta wọ̀nyí dúró fún?7 Nígbà náà ni ̀yin yóò wọn lóhùn , nítorí a omi odò Jordani kúrò iwájú àpótí ̀Olúwa. Nígbà a rékọjá a Jordani, a omi Jordani kúrò. Àwọn òkúta wọ̀nyí yóò jẹ́ ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli láéláé."

8 Báyìí ni àwọn ọmọ Israẹli ṣe Joṣua ti pàṣẹ fún wọn. Wọ́n gbé òkúta méjìlá láti àárín odò Jordani gẹ́gẹ́ iye ̀àwọn ọmọ Israẹli, Olúwa ti sọ fún Joṣua; wọ́n wọ́n kọjá lọ ibùdó, ibi wọ́n ti gbé wọn kalẹ̀. 9 Joṣua to òkúta méjìlá náà àárín odò Jordani fún ìrántí ̀kánkán ibi àwọn àlùfáà ó ru àpótí ̀dúró . Wọ́n níbẹ̀ di òní yìí.

10 Àwọn àlùfáà ó ru àpótí náà dúró àárín Jordani títí gbogbo nǹkan Olúwa pàṣẹ fún Joṣua fi di ṣíṣe nípasẹ̀ àwọn ènìyàn, gẹ́gẹ́ Mose ti pàṣẹ fún Joṣua. Àwọn ènìyàn náà yára kọjá, 11 gbogbo wọn ti rékọjá tán, ni àpótí ̀Olúwa àti àwọn àlùfáà òdìkejì. àwọn ènìyàn ti ń wọ́n. 12 Àwọn ọkùnrin Reubeni, Gadi àti ìdajì ̀Manase náà rékọjá ìhámọ́ra ogun níwájú àwọn ọmọ Israẹli, gẹ́gẹ́ Mose ti pàṣẹ fún wọn. 13 Àwọn ̀kẹ́ méjì (40,000) ti múra fún ogun rékọjá lọ iwájú Olúwa pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jeriko láti jagun.

14 ọjọ́ náà ni Olúwa gbé Joṣua ga ojú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n bẹ̀u rẹ̀ gbogbo ọjọ́ ayé e wọn, gẹ́gẹ́ wọ́n ti bẹ̀Mose.

15 Olúwa sọ fún Joṣua , 16 "Pàṣẹ fún àwọn àlùfáà o ń ru àpótí ̀, wọn ó jáde kúrò nínú odò Jordani."

17 Bẹ́̀ ni Joṣua pàṣẹ fún àwọn àlùfáà , "jáde kúrò nínú odò Jordani."

18 Àwọn àlùfáà náà jáde láti inú odò pẹ̀àpótí ̀Olúwa ni orí wọn. wọ́n ti fi ẹsẹ̀ wọn tẹ orí ilẹ̀ gbígbẹ ni omi Jordani náà padà ààyè e rẹ̀, o kún wọ bèbè i ti àtẹ̀yìnwá.

19 ọjọ́ kẹwàá oṣù kìn-ín-ní àwọn ènìyàn náà lọ láti Jordani, wọ́n dúró Gilgali ìlà-oòrùn Jeriko. 20 Joṣua to àwọn òkúta méjìlá wọ́n jáde Jordani jọ Gilgali. 21 Ó sọ fún àwọn ará Israẹli, "ọjọ́ iwájú nígbà àwọn ọmọ yín béèrè ọwọ́ baba wọn , Kín ni òkúta wọ̀nyí dúró fún?22 Nígbà náà ni ó jẹ́ àwọn ọmọ yín mọ̀ , Israẹli rékọjá odò Jordani orí ilẹ̀ gbígbẹ.23 Nítorí Olúwa Ọlọ́run yín Jordani gbẹ iwájú u yín títí ̀yin fi kọjá. Olúwa Ọlọ́run yín ti ṣe Jordani gẹ́gẹ́ ó ti ṣe Òkun Pupa, nígbà ó un gbẹ iwájú wa títí àwa fi kọjá. 24 Ó ṣe èyí gbogbo ayé mọ̀ ọwọ́ Olúwa agbára, àti ̀yin ó máa bẹ̀Olúwa Ọlọ́run yín ìgbà gbogbo."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-