Pular para o conteúdo
Publicidade

Levítico 21

Òfin fún àwọn àlùfáà

1 21.1-3: El 44.25. Olúwa sọ fún Mose pe, "àwọn àlùfáà wọ́n jẹ́ ọmọ Aaroni sọ̀rọ̀, o sọ fún wọn , Ẹnikẹ́ni nínú wọn gbọdọ̀ sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́ nítorí àwọn ènìyàn wọn ó . 2 Ṣùgbọ́n ó ṣe àwọn ó súnmọ́ ọn ìyá rẹ̀, baba rẹ̀, ọmọ rẹ̀ ọkùnrin tàbí obìnrin, àti arákùnrin rẹ̀. 3 Tàbí fún arábìnrin rẹ̀ ì ì wọ ilé ọkọ ó ń gbé lọ́dọ̀ rẹ̀. Nítorí arábìnrin bẹ́̀, ó sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́. 4 Nítorí ó jẹ́ olórí, òun gbọdọ̀ sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́, bẹ́̀ ni gbọdọ̀ ba ara rẹ̀ jẹ́ láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀.

5 21.5: Le 19.27; De 14.1. " Àlùfáà gbọdọ̀ irun orí rẹ̀ bẹ́̀ ni gbọdọ̀ rẹ́ irùngbọ̀n rẹ̀. gbọdọ̀ fi abẹ ya ara rẹ̀ láti fihàn òun ipò ̀fọ̀. 6 Wọ́n gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́ fún Ọlọ́run, wọ́n ba à sọ orúkọ Ọlọ́run wọn di àìmọ́, nítorí àwọn ni wọ́n ń fi iná sun ẹbọ Olúwa wọn, ti ó jẹ oúnjẹ Ọlọ́run wọn. Nítorí náà wọn gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́.

7 " Àwọn àlùfáà gbọdọ̀ fẹ́ panṣágà tàbí obìnrin ó ti fi ọkùnrin ba ara rẹ̀ jẹ́ tàbí obìnrin ọkọ rẹ̀ ti kọ̀sílẹ̀ nítorí àwọn àlùfáà jẹ́ mímọ́ Ọlọ́run wọn. 8 Àwọn ènìyàn gbọdọ̀ máa wọ́n mímọ́, nítorí àwọn ni wọ́n ń ẹbọ oúnjẹ fún mi. Èmi ni Olúwa, mo jẹ́ mímọ́, mo ya àwọn ènìyàn mi mímọ́.

9 " ọmọbìnrin àlùfáà kan fi iṣẹ́ àgbèrè ba ara rẹ̀ jẹ́, ó dójútì baba rẹ̀, iná ni a ó sun ún.

10 " Lẹ́yìn a ti fi òróró yan olórí àlùfáà láàrín àwọn arákùnrin rẹ̀, a ti fi àmì òróró yàn án láti máa wọ aṣọ àlùfáà, ó gbọdọ̀ tọ́irun orí rẹ̀, bẹ́̀ ni gbọdọ̀ fa aṣọ rẹ̀ ya láti fihàn òun ipò ̀fọ̀. 11 ó ma ṣe wọlé tọ òkú lọ, ó ṣe sọ ará rẹ di àìmọ́ nítorí baba tàbí nítorí ìyá rẹ̀. 12 gbọdọ̀ kúrò ibi mímọ́ Ọlọ́run tàbí ó sọ ́ di aláìmọ́ torí a ti fi ìfòróróyàn Ọlọ́run á mímọ́. Èmi ni Olúwa.

13 " Ọmọbìnrin yóò fẹ́ gbọdọ̀ jẹ́ ẹni mọ ọkùnrin . 14 gbọdọ̀ fẹ́ opó tàbí ẹni a kọ̀sílẹ̀ tàbí obìnrin ó ti fi àgbèrè ba ara rẹ̀ jẹ́, ṣùgbọ́n ó fẹ́ obìnrin mọ ọkùnrin , láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀. 15 ó ba à sọ di aláìmọ́ nínú àwọn ènìyàn rẹ̀. Èmi ni Olúwa ó sọ ́ di mímọ́.’ "

16 Olúwa Mose sọ̀rọ̀ , 17 "Sọ fún Aaroni , Ẹnikẹ́ni nínú irú-ọmọ rẹ̀ ìran-ìran wọn, ó ààrùn kan, ó ṣe súnmọ́ tòsí láti ẹbọ ohun jíjẹ Ọlọ́run rẹ̀. 18 Ẹnikẹ́ni ó àbùkù gbọdọ̀ súnmọ́ ibi ẹbọ náà. gbọdọ̀ afọ́tàbí arọ, alábùkù ara tàbí àwọn ara wọn . 19 gbọdọ̀ ẹnikẹ́ni yálà ó rọ lápá lẹ́sẹ̀, 20 tàbí ó jẹ́ abuké, tàbí ó ya aràrá tàbí ó àìsàn ojú tàbí ó egbò tàbí a ti yọ nǹkan ọmọkùnrin rẹ̀. 21 Ẹnikẹ́ni ó àbùkù nínú irú-ọmọ Aaroni àlùfáà gbọdọ̀ súnmọ́ tòsí láti ẹbọ fi iná sun Olúwa. Nítorí ó jẹ́ alábùkù, gbọdọ̀ súnmọ́ tòsí láti ẹbọ àkàrà Ọlọ́run rẹ̀. 22 Ó jẹ́ oúnjẹ Ọlọ́run rẹ̀ tàbí èyí ó mọ́ jùlọ, ṣùgbọ́n torí ó àbùkù gbọdọ̀ súnmọ́ ibi aṣọ títa tàbí pẹpẹ. 23 Nípa ṣíṣe bẹ́̀ yóò ba ibi mímọ́ mi jẹ́ torí , Èmi Olúwa ti sọ wọ́n di mímọ́.’ "

24 Wọ̀nyí ni àwọn ohun Mose sọ fún Aaroni, àwọn ọmọ Aaroni àti gbogbo ọmọ Israẹli.

Veja também