Publicidade

Levítico 26

Èrè ìgbọ́ràn

1 " 26.1: Le 19.4; El 20.4,23; De 4.15-18; 27.15.̀yin gbọdọ̀ mọ ère òrìṣà, tàbí ̀yin gbe ère kalẹ̀ tàbí ̀yin gbẹ́ ère òkúta: ̀yin gbẹ́ òkúta ̀yin yóò gbé kalẹ̀ láti sìn. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.

2 26.2: El 20.8; 23.12; 34.21; 35.2,3; Le 19.3,30; De 5.12-15. " pa ọjọ́ ìsinmi mi mọ́ ̀yin bọ̀wọ̀ fún ibi mímọ́ mi. Èmi ni Olúwa.

3 26.3-13: De 7.12-26; 28.1-14. " ̀yin tẹ̀àṣẹ mi, ̀yin ṣọ́ra láti pa òfin mi mọ́. 4 Èmi yóò rọ̀fún yín àkókò rẹ̀, ilẹ̀ yín le èso rẹ̀ jáde ó yẹ àwọn igi eléso yín so èso. 5 Èrè oko yín yóò pọ̀ bi ó máa pa ọkà títí di àsìkò ìkórè igi eléso, ̀yin yóò máa gbé ilẹ̀ yín láìléwu.

6 " Èmi yóò fún yín àlàáfíà ilẹ̀ yín, ̀yin yóò sùn láìsí ìbẹ̀ẹnikẹ́ni. Èmi yóò gbogbo ẹranko búburú kúrò ilẹ̀ náà, bẹ́̀ ni idà yóò la ilẹ̀ yín . 7 ̀yin yóò àwọn ̀yín, wọn yóò tipa idà . 8 Àwọn márùn-ún péré nínú yín yóò máa ṣẹ́gun ọgọ́rùn-ún ènìyàn, àwọn ọgọ́rùn-ún yóò máa ṣẹ́gun ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000), àwọn ̀yín yóò tipa idà níwájú yín.

9 " Èmi yóò fi ojúrere yín, Èmi yóò i, Èmi yóò jẹ́ pọ̀ i, Èmi yóò pa májẹ̀mi mọ́ pẹ̀yín. 10 Àwọn èrè oko yín yóò pọ̀ bẹ́̀ ̀yin ó máa jẹ èrè ọdún ó kọjá, ̀yin ó wọn jáde, ̀yin ààyè tuntun . 11 26.11,12: 2Kọ 6.16.Èmi yóò kọ́ àgọ́ mímọ́ mi àárín yín. Èmi kórìíra yín. 12 Èmi yóò pẹ̀yín, Èmi yóò máa jẹ́ Ọlọ́run yín, ̀yin yóò máa jẹ́ ènìyàn mi. 13 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín ó yín jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti, ̀yin ba à jẹ́ ẹrú fún wọn mọ́. Mo ìdè àjàgà yín, mo ̀yin máa rìn gẹ́gẹ́ ẹni a gbé lórí sókè.

Ìjìyà fún àìgbọ́ràn

14 26.14-45: De 28.16-68. " ̀yin fetí mi ̀yin ṣe gbogbo òfin wọ̀nyí. 15 ̀yin kọ àṣẹ mi ̀yin kórìíra òfin mi, ̀yin kùnà láti pa ìlànà mi mọ́, nípa èyí ̀yin ti ṣẹ̀ májẹ̀mi. 16 Èmi yóò ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí yín, Èmi yóò ìpayà òjijì yín: àwọn ààrùn afiniṣòfò, àti ibà afọ́nilójú, í pa ni díẹ̀díẹ̀. ̀yin yóò gbin èso ilẹ̀ yín lásán, nítorí àwọn ̀yín ni yóò jẹ gbogbo ohun ̀yin ti gbìn. 17 Èmi yóò dojúkọ yín títí ̀yin ó fi di ẹni ìkọlù; àwọn ó kórìíra yín ni yóò ṣe àkóso lórí yín. Ìbẹ̀yóò yín bi ̀yin yóò máa káàkiri nígbà ẹnikẹ́ni yín.

18 " ̀yin gbọ́ tèmi lẹ́yìn gbogbo èyí, Èmi yóò fi kún ìyà yín ìlọ́po méje nítorí ̀ṣẹ̀ yín. 19 Èmi yóò fọ́ agbára ìgbéraga yín, ojú ̀run yóò le koko irin, ilẹ̀ yóò le idẹ (òjò rọ̀: ilẹ̀ yín yóò le). 20 ó máa lo agbára yín lásán torí ilẹ̀ yín yóò so èso, bẹ́̀ ni àwọn igi yín yóò so èso pẹ̀.

21 " tẹ̀síwájú láì gbọ́ tèmi, Èmi yóò tún fa ìjayà yín le ìgbà méje gẹ́gẹ́ ̀ṣẹ̀ yín. 22 Èmi yóò rán àwọn ẹranko búburú àárín yín, wọn yóò pa àwọn ọmọ yín, wọn yóò run agbo ẹran yín, díẹ̀ nínú yín ni wọn yóò ṣẹ́àwọn ̀yín di ahoro.

23 " tún yípadà lẹ́yìn gbogbo ìjìyà wọ̀nyí, tẹ̀síwájú láti lòdì mi. 24 Èmi náà yóò lòdì yín. Èmi yóò tún fa ìjìyà yín le ìlọ́po méje ju ti ìṣáájú. 25 Èmi yóò idà yín nítorí ̀ṣẹ̀ yín láti fi gbẹ̀san májẹ̀mi pamọ́. ba sálọ ìlú yín fún ààbò, Èmi yóò rán àjàkálẹ̀-ààrùn àárín yín, àwọn ̀yín, yóò ṣẹ́gun yín. 26 Èmi yóò ìpèsè oúnjẹ yín dúró, bi : inú ààrò kan ni obìnrin mẹ́wàá yóò ti máa se oúnjẹ yín. Òsùwọ̀n ni wọn yóò fi máa yọ oúnjẹ yín, ó jẹ ṣùgbọ́n, .

27 " Lẹ́yìn gbogbo èyí, gbọ́ tèmi, lòdì mi, 28 ìbínú mi, èmi yóò korò yín, èmi tìkára mi yóò fìyà jẹ yín ìgbà méje nítorí ̀ṣẹ̀ yín. 29 Ebi náà yóò pa yín bi ó máa jẹ ẹran-ara àwọn ọmọ yín ọkùnrin, àti àwọn ọmọ yín obìnrin. 30 Èmi yóò àwọn pẹpẹ òrìṣà yín, lórí òkè níbi ti ń sìn, Èmi yóò òkú yín jọ, sórí àwọn òkú òrìṣà yín. Èmi ó kórìíra yín. 31 Èmi yóò sọ àwọn ìlú yín di ahoro, èmi yóò ba àwọn ilé mímọ́ yín jẹ́. Èmi yóò gbọ́ òórùn dídùn yín mọ́. 32 Èmi yóò pa ilẹ̀ yín run bi ẹnu yóò ya àwọn ̀yín ó gbé ilẹ̀ náà. 33 Èmi yóò yín sínú àwọn orílẹ̀-èdè, Èmi yóò yọ idà yín lẹ́yìn, ilẹ̀ yín yóò di ahoro, àwọn ìlú yín ni a ó parun. 34 Ilẹ̀ náà yóò ìsinmi fún gbogbo ìgbà fi ilẹ̀ àjèjì fi ó. Ilẹ̀ náà yóò sinmi láti fi dípò ọdún kọ̀ láti fún un. 35 Níwọ́n ìgbà ó, ilẹ̀ náà yóò ìsinmi lákòókò ìsinmi rẹ̀ lákokò fi ń gbé orí rẹ̀.

36 " Èmi yóò jẹ́ ó burú fún àwọn ó ilẹ̀ ìgbèkùn bi ìró ewé ń lásán yóò máa wọn . ó máa ẹni ń fún idà. ó ṣubú láìsí ̀láyìíká yín. 37 Wọn yóò máa ṣubú lu ara wọn, ẹni ń fún idà nígbà ẹni ń yín. ̀yin yóò agbára láti dúró níwájú ̀yín. 38 ̀yin yóò ṣègbé láàrín àwọn orílẹ̀-èdè abọ̀rìṣà. Ilẹ̀ ̀yín yóò jẹ yín run. 39 Àwọn ó ṣẹ́nínú yín ni yóò ṣòfò dànù ilẹ̀ ̀yín torí ̀ṣẹ̀ yín àti ti àwọn baba ńlá yín.

40 26.40,41: Ap 7.51. " wọ́n jẹ́wọ́ ̀ṣẹ̀ wọn àti ti baba ńlá wọn, ìwà ìṣọ̀tẹ̀ wọn àti wọ́n ti ṣe lòdì mi. 41 Èyí mi lòdì wọn mo fi wọn lọ ilẹ̀ àwọn ̀wọn. Nígbà wọ́n rẹ àìkọlà àyà wọn sílẹ̀ wọ́n gba ìbáwí ̀ṣẹ̀ wọn. 42 Nígbà náà ni Èmi yóò rántí májẹ̀mi pẹ̀Jakọbu àti pẹ̀Isaaki àti pẹ̀Abrahamu, Èmi yóò rántí ilẹ̀ náà. 43 Àwọn ènìyàn náà yóò fi ilẹ̀ náà sílẹ̀, yóò ìsinmi rẹ̀ nígbà ó lófo láìsí wọn níbẹ̀. Wọn yóò jìyà ̀ṣẹ̀ wọn torí wọ́n kọ àwọn òfin mi. Wọ́n kórìíra àwọn àṣẹ mi. 44 Pẹ̀gbogbo nǹkan wọ̀nyí, nígbà wọ́n nílé àwọn ̀wọn, èmi yóò ta wọ́n , bẹ́̀ ni èmi yóò kórìíra wọn pátápátá, èyí ó mi májẹ̀mi pẹ̀wọn. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn. 45 Nítorí wọn, èmi ó rántí májẹ̀mi mo ti ṣe pẹ̀baba ńlá wọn. Àwọn mo jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti lójú gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè láti jẹ́ Ọlọ́run wọn. Èmi ni Olúwa.’ "

46 Ìwọ̀nyí ni òfin àti ìlànà Olúwa fún Mose orí òkè Sinai láàrín òun àti àwọn ọmọ Israẹli.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-