Pular para o conteúdo
Publicidade

Adoração

Por Bíblia Online

A adoração é a resposta do coração humano à majestade de Deus. Deus é Espírito e importa que os que o adoram o adorem em espírito e em verdade — com todo o ser.

Adorar em espírito

Deus é Espírito e importa que os adoradores o adorem em espírito e em verdade. A adoração verdadeira brota do coração.

̀ni Ọlọ́run: àwọn ẹni ń sìn ín ṣe aláìsìn ín ̀àti òtítọ́."

Ṣùgbọ́n àkókò ń bọ̀, ó tán nísinsin yìí, nígbà àwọn olùsìn tòótọ́ yóò máa sin Baba ̀àti òtítọ́, nítorí irú wọn ni Baba ń ó máa sin òun. ̀ni Ọlọ́run: àwọn ẹni ń sìn ín ṣe aláìsìn ín ̀àti òtítọ́."

Jesu fún un , "Gbà gbọ́ obìnrin yìí, àkókò náà ń bọ̀, nígbà yóò ṣe lórí òkè yìí tàbí Jerusalẹmu ni ̀yin ó máa sin Baba. ̀yin ń sin ohun ̀yin mọ̀, àwa ń sin ohun àwa mọ̀, nítorí ìgbàlà ti ̀dọ̀ àwọn Júù . Ṣùgbọ́n àkókò ń bọ̀, ó tán nísinsin yìí, nígbà àwọn olùsìn tòótọ́ yóò máa sin Baba ̀àti òtítọ́, nítorí irú wọn ni Baba ń ó máa sin òun.

Ó , "Olúwa, mo gbàgbọ́," ó wólẹ̀ fún un.

Jesu fún un , "Padà kúrò lẹ́yìn mi, Satani! Nítorí a ti kọ ́ , Olúwa Ọlọ́run rẹ ni ìwọ ó fi orí balẹ̀ fún, òun nìkan ṣoṣo ni ìwọ máa sìn.’ "

Jesu dáhùn ó fún un , "Kúrò lẹ́yìn mi, Satani, nítorí a kọ̀rẹ̀ , Ìwọ foríbalẹ̀ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ, òun nìkan ṣoṣo ni ìwọ ó máa sìn.’ "

Ẹbọ ààyè mímọ́

Nítorí náà mo fi ìyọ́Ọlọ́run bẹ̀ yín ará, ̀yin ó fi ara yín fún Ọlọ́run ẹbọ ààyè mímọ́, ìtẹ́wọ́gbà, èyí ni iṣẹ́ ìsìn yín ó tọ̀.

Ẹbọ ààyè mímọ́

Nítorí náà mo fi ìyọ́Ọlọ́run bẹ̀ yín ará, ̀yin ó fi ara yín fún Ọlọ́run ẹbọ ààyè mímọ́, ìtẹ́wọ́gbà, èyí ni iṣẹ́ ìsìn yín ó tọ̀. da ara yín pọ̀ mọ́ ayé yìí; ṣùgbọ́n paradà láti di tuntun èrò inú yín, ̀yin ó ìdí ìfẹ́ Ọlọ́run, ó dára, ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà, ti ó .

Nítorí láti ̀dọ̀ rẹ̀, àti nípa rẹ̀, àti fún un ni ohun gbogbo;

ẹni ògo fún láéláé! Àmín.

A ti kọ ìwé rẹ̀ :

" Níwọ́n ìgbà mo láààyè,ni Olúwa ,

gbogbo eékún ni yóò wólẹ̀ fún mi;

gbogbo ahọ́n ni yóò jẹ́wọ́ fún Ọlọ́run.’ "

Louvor e reverência

Vinde, adoremos e prostremo-nos. Louvai ao Senhor! Todo ser que respira louve o nome glorioso do Senhor.

, jẹ́ a foríbalẹ̀ a sìn ín,

jẹ́ a kúnlẹ̀ níwájú

Olúwa ẹni ó wa,

, jẹ́ a foríbalẹ̀ a sìn ín,

jẹ́ a kúnlẹ̀ níwájú

Olúwa ẹni ó wa,

fi ìyìn fún Olúwa.

fi ìyìn fún Ọlọ́run ibi mímọ́ rẹ̀,

yìn ín nínú agbára ̀run rẹ̀.

yìn ín fún iṣẹ́ agbára rẹ̀.

yìn ín fún títóbi rẹ̀ ó tayọ̀.

fi ohùn ìpè yìn ín.

fi ohun èlò orin yìn ín.

fi ohun èlò orin àti ijó yìn ín

fi ohun èlò orin olókùn àti ìpè yìn ín,

yìn ín pẹ̀aro olóhùn òkè,

yìn ín lára aro olóhùn gooro.

Jẹ́ gbogbo ohun ó ̀yin Olúwa.

fi ìyìn fún Olúwa.

Jẹ́ gbogbo ohun ó ̀yin Olúwa.

fi ìyìn fún Olúwa.

lọ ẹnu-ọ̀rẹ̀ pẹ̀ọpẹ́

àti àgbàlá rẹ̀ pẹ̀ìyìn;

fi ọpẹ́ àti ìyìn fún orúkọ rẹ̀.

Fi fún Olúwa, àní ògo orúkọ rẹ̀;

sin Olúwa nínú ẹwà ìwà mímọ́.

ìhó ayọ̀ Ọlọ́run, ̀yin ilẹ̀ gbogbo!

kọrin ọlá orúkọ rẹ̀;

kọrin ìyìnsí i.

fún Ọlọ́run , "Ìwọ ti ̀nínú iṣẹ́ rẹ!

Nípa ̀pọ̀ agbára rẹ

ni àwọn ̀rẹ yóò fi sìn ́.

Gbogbo ayé ń wólẹ̀ fún ;

wọn ń kọrin ìyìn ,

wọ́n ń kọrin ìyìn orúkọ rẹ." Sela.

Mo fi ẹnu mi kígbe sókè i,

ìyìn rẹ̀ ẹnu mi.

Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ìwọ

yóò láti jọ́sìn níwájú rẹ, Olúwa;

wọn ó ògo fún orúkọ rẹ̀.

Nítorí ìwọ tóbi, ìwọ ń ṣe ohun ìyanu;

ìwọ nìkan ni Ọlọ́run.

Yin Olúwa, ìwọ ọkàn mi; àti gbogbo ohun ó nínú mi, yín orúkọ rẹ̀ mímọ́.

fi ọpẹ́ fún Olúwa, pe orúkọ rẹ̀,

jẹ́ a mọ ohun ó ṣe láàrín àwọn orílẹ̀-èdè.

Ọlọ́run, ìwọ ni Ọlọ́run mi,

nígbà gbogbo ni mo ń ṣàfẹ́rẹ,

òǹgbẹ rẹ ń gbẹ ọkàn mi,

ara mi ,

ilẹ̀ gbígbẹ àti ilẹ̀ ń ṣàárẹ̀

níbi omi.

Nítorí ìfẹ́ rẹ dára ju ayé lọ,

ètè mi yóò fògo fún .

Èmi ó yìn ́ níwọ̀n ìgbà mo láààyè,

èmi ó gbé ọwọ́ sókè, èmi ó pe orúkọ rẹ.

Declarações de adoração

Tu és digno, Senhor, de receber glória e honra! Ao Senhor pertence a grandeza, o poder, a glória e a majestade.

"Olúwa àti Ọlọ́run, ìwọ ni o yẹ,

láti gba ògo àti ọlá àti agbára,

nítorí ìwọ ni o ohun gbogbo,

àti nítorí ìfẹ́ inú rẹ̀ ni

wọn fi a wọn."

Ó ń ni ohùn rara , "bẹ̀Ọlọ́run, fi ògo fún un, nítorí wákàtí ìdájọ́ rẹ̀ : foríbalẹ̀ fún ẹni o ̀run, àti ayé, àti Òkun, àti àwọn orísun omi!"

Ta ni yóò bẹ̀, Olúwa,

yóò fi ògo fún orúkọ rẹ̀?

Nítorí ìwọ nìkan ṣoṣo ni mímọ́.

Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ni yóò ,

ti yóò foríbalẹ̀ níwájú rẹ,

nítorí a ti fi ìdájọ́ rẹ hàn."

Èmi, Johanu, ni ẹni ó gbọ́ ó ri nǹkan wọ̀nyí. Nígbà mo gbọ́ mo , mo wólẹ̀ láti foríbalẹ̀ níwájú ẹsẹ̀ angẹli náà, o fi nǹkan wọ̀nyí hàn mi. Nígbà náà ni ó fún mi , "ò, ṣe bẹ́̀, ìránṣẹ́ ẹlẹgbẹ́ rẹ ni èmi, àti ti àwọn arákùnrin rẹ̀ wòlíì, àti ti àwọn ń pa ̀rọ̀ inú ìwé yìí mọ́. Foríbalẹ̀ fún Ọlọ́run!"

Tìrẹ Olúwa ni títóbi àti agbára pẹ̀ìyìn

àti ọláńlá àti dídán,

nítorí gbogbo nǹkan ̀run àti ayé jẹ́ tìrẹ.

Tìrẹ Olúwa ni ìjọba;

a gbé ga gẹ́gẹ́ orí lórí ohun gbogbo.

Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí ó dára;

ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láé.

lóhùn rara, "Gbà , Ọlọ́run olùgbàlà a wa;

wa jọ o gbà kúrò lọ́wọ́ àwọn orílẹ̀-èdè,

àwa ó fi ọpẹ́ fún orúkọ mímọ́ rẹ,

àwa ó yọ̀ nínú ìyìn rẹ̀."

Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,

láé àti láéláé.

Lẹ́yìn náà gbogbo àwọn ènìyàn , "Àmín," wọ́n "Yin Olúwa."

Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí ó dára;

ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láé.

kọrin i, kọrin ìyìn, i,

sọ ti gbogbo iṣẹ́ ìyanu rẹ̀.

Nítorí náà, Ọlọ́run ti gbé e ga ipele ó ga jùlọ,

ó ti fi orúkọ kan ti ó borí gbogbo orúkọ fún un,

ni orúkọ Jesu ni gbogbo eékún máa wólẹ̀,

̀run, àti orí ilẹ̀ ayé àti ìsàlẹ̀ ilẹ̀ ayé,

àti gbogbo ahọ́n jẹ́wọ́ , Jesu Kristi ni Olúwa,

fún ògo Ọlọ́run Baba.

Sacrifício de louvor

Por meio de Jesus ofereçamos sempre sacrifício de louvor. Cantai ao Senhor, celebrai em salmos — enchei-vos do Espírito.

Ǹjẹ́ nípasẹ̀ rẹ̀, jẹ́ a máa ẹbọ ìyìn si Ọlọ́run nígbà gbogbo, èyí yìí ni èso ètè wa, ń jẹ́wọ́ orúkọ rẹ̀.

Nítorí náà àwa ń gbà ilẹ̀ ọba ti a , jẹ́ a ọpẹ́ nípa èyí ti a fi máa sin Ọlọ́run ni ìtẹ́wọ́gbà pẹ̀̀wọ̀ àti ìbẹ̀rẹ̀. Nítorí , "Ọlọ́run wa, iná ti ń ni run ni."

máa ara yín sọ̀rọ̀ nínú Saamu, àti orin ìyìn, àti orin ̀, máa kọrin, máa kọrin dídùn ọkàn yín Olúwa.

jẹ́ ̀rọ̀ Kristi máa gbé inú yín ̀pọ̀lọpọ̀ nínú ọgbọ́n gbogbo; máa kọ́ , máa gba ara yín níyànjú nínú Saamu, àti orin ìyìn, àti orin ̀, máa kọrin Ọlọ́run ọkàn ọpẹ́.

Ṣùgbọ́n láàrín ̀gànjọ́ Paulu àti Sila ń gbàdúrà, wọ́n ń kọrin ìyìn si Ọlọ́run, àwọn ara túbú ń tẹ́wọn.

Ọlọ́run gbogbo ìtùnú

Olùbùkún ni Ọlọ́run, àti Baba Jesu Kristi Olúwa wa, Baba ìyọ́, àti Ọlọ́run ìtùnú gbogbo. Ẹni ń nínú ni gbogbo ìdààmú wa, ki àwa pẹ̀máa tu àwọn ó nínú ìdààmú nínú, nípá ìtùnú náà ti a fi ń àwa fúnra wa nínú láti ̀dọ̀ Ọlọ́run .

Àwa ń sọ fún yín, èyí àwa ti , àwa ti gbọ́, ̀yin pẹ̀ó ìdàpọ̀ pẹ̀wa. Nítòótọ́ ìdàpọ̀ wa ń bẹ pẹ̀Baba àti pẹ̀ọmọ rẹ̀, Jesu Kristi.

Adoração como vida

Exaltai ao Senhor, prostrai-vos ante o escabelo dos seus pés. A adoração genuína transforma o adorador e agrada o Criador.

Gbígbéga ni Olúwa Ọlọ́run wa

foríbalẹ̀ níbi ẹsẹ̀ rẹ̀; ó jẹ́ mímọ́.

Ìyìn rẹ̀ kún ẹnu mi,

ó ń sọ ti ọlá rẹ ọjọ́ gbogbo.

kọrin Ọlọ́run,

kọrin ìyìn i,

la ̀fún ẹni ń rékọjá aginjù.

Olúwa ni orúkọ rẹ̀, máa yọ̀ níwájú rẹ̀.

Baba àwọn aláìní baba àti onídàájọ́ àwọn opó ni Ọlọ́run ibùgbé

rẹ̀ mímọ́

Èmi ó fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí òdodo rẹ̀,

èmi ó kọrin ìyìn Olúwa ̀gá-ògo jùlọ.

Èmi yóò kéde orúkọ rẹ láàrín arákùnrin àti arábìnrin mi;

nínú ìjọ ni èmi yóò máa yìn ́.

̀yin bẹ̀Olúwa, yìn ín!

Gbogbo ̀yin ìran Jakọbu, fi ògo fún un!

dìde fún un tẹ̀tẹ̀, ̀yin irú-ọmọ Israẹli!

Èmi na ọwọ́ mi jáde :

òǹgbẹ rẹ gbẹ ọkàn mi i ìyàngbẹ ilẹ̀. Sela.

Èéṣe ìwọ fi ń rẹ̀wẹ̀, ìwọ ọkàn mi?

Èéṣe ara rẹ fi lélẹ̀ nínú mi?

Fi ìrètí rẹ sínú Ọlọ́run,

nítorí èmi yóò máa yìn ín, Òun ni

Olùgbàlà mi àti Ọlọ́run mi.

Mo sọ fún Olúwa, "Ìwọ ni Olúwa mi,

lẹ́yìn rẹ èmi ìre kan."

sin Olúwa pẹ̀ìbẹ̀

máa yọ̀ pẹ̀ìwárìrì.

Inú mi yóò dùn, èmi yóò yọ̀ nínú rẹ;

èmi ó kọrin ìyìn orúkọ rẹ, Ìwọ ̀gá-Ògo jùlọ.

Falsa adoração

Não terás outros deuses diante de mim. Não adorarás ídolos. A adoração exclusiva ao Senhor é mandamento inegociável.

Ìwọ gbọdọ̀ tẹ orí ara rẹ ba fún wọn, bẹ́̀ ni ìwọ gbọdọ̀ sìn wọ́n; nítorí Èmi Olúwa Ọlọ́run rẹ, Ọlọ́run owú ni , ń bẹ ̀ṣẹ̀ àwọn baba lára àwọn ọmọ, láti ìran kẹta títí ̀kẹrin nínú àwọn ó kórìíra mi.

ṣe sin ọlọ́run mìíràn, nítorí Olúwa, orúkọ ẹni ti ń jẹ́ Òjòwú, Ọlọ́run owú ni.

Mose ṣe wọ inú àgọ́ náà, ̀wọ́n àwọsánmọ̀ yóò sọ̀kalẹ̀, yóò dúró ẹnu ọnà, nígbà Olúwa ń sọ̀rọ̀ pẹ̀Mose. Nígbàkígbà àwọn ènìyàn i ti ̀wọ́n àwọsánmọ̀ dúró ẹnu-ọ̀àgọ́, gbogbo wọn yóò dìde wọn yóò sìn, olúkúlùkù ẹnu-ọ̀àgọ́ rẹ̀.

Olúwa ni agbára àti orin mi;

òun ti di Olùgbàlà mi,

òun ni Ọlọ́run mi, èmi ó yìn ín,

Ọlọ́run baba mi, èmi ó gbé e ga.

Ta ni nínú àwọn òrìṣà

dàbí rẹ, Olúwa?

Ta dàbí rẹ:

títóbi,

mímọ́ Ẹlẹ́ni yìn,

ń ṣe ohun ìyanu?

̀yin yóò máa sin Olúwa Ọlọ́run yin, òun yóò si bùsi oúnjẹ rẹ. Èmi yóò àìsàn kúrò láàrín rẹ.

Òun ni ìyìn in yín, Òun ni Ọlọ́run yín, ó ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu ńlá àti ohun ̀, fojú ara yín .

Níwájú Olúwa Ọlọ́run yín níbẹ̀, ̀yin àti ìdílé yín jẹun , nínú gbogbo ìdáwọ́e yín, torí Olúwa Ọlọ́run yín ti bùkún un yín.

Wọ́n fi òrìṣà un jowú,

ohun ìríra ni wọ́n fi un bínú.

Wọ́n ẹbọ iwin búburú, í ṣe Ọlọ́run,

ọlọ́run wọn mọ̀ ,

ọlọ́run ó ṣẹ̀ṣẹ̀ farahàn láìpẹ́,

ọlọ́run àwọn baba yín bẹ̀.

Ìwọ rántí àpáta, ó ;

o gbàgbé Ọlọ́run ó .

ṣọ́ra, a ba à tàn yín jẹ láti yípadà sin ọlọ́run mìíràn àti láti máa foríbalẹ̀ fún wọn.

Olúwa :

"Àwọn ènìyàn yìí súnmọ́ ̀dọ̀ mi pẹ̀ẹnu wọn,

wọ́n bọ̀wọ̀ fún mi pẹ̀ètè wọn,

ṣùgbọ́n ọkàn wọn jìnnà mi.

Ìsìn wọn si mi

ni a gbé ka orí òfin àwọn

ọkùnrin kọ́ ni.

yin Olúwa

Olúwa, ìwọ ni Ọlọ́run mi;

èmi yóò gbé ga èmi ó

fi ìyìn fún orúkọ rẹ

nítorí nínú òtítọ́ aláìlẹ́gbẹ́

o ti ṣe ohun ńlá,

àwọn ohun o ti gbèrò o rẹ̀ lọ́jọ́ pípẹ́.

Ọlọ́run padà, ó fi wọn sílẹ̀ láti máa sin ogun ̀run: òòrùn, òṣùpá àti ìràwọ̀. Èyí ìbámu pẹ̀a ti kọ ́ nínú ìwé àwọn wòlíì :

" ̀yin ha ẹran a pa àti ẹbọ wa fún mi

ogójì ọdún ijù , ìwọ ilé Israẹli?

̀yin tẹ́wọ́gbà àgọ́ Moleki,

àti ìràwọ̀ Refani òrìṣà yín,

àwòrán ̀yin ṣe láti máa bọ wọ́n.

Nítorí náà èmi yóò yín lọ ìgbèkùn rékọjá Babeli.

ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni ó inú dídùn nínú ìrẹ̀lẹ̀ èké àti bíbọ àwọn angẹli lọ́ èrè yín gbà lọ́wọ́ yín, ẹni ń dúró lórí nǹkan wọ̀n-ọn-nì ó ti , ó ń ṣe féfé asán nípa èrò ti ọkàn ara rẹ̀. Wọn ti sọ ìdàpọ̀ wọn pẹ̀ẹni i ṣe orí nu, láti ̀dọ̀ ẹni a ń ti ipa oríkèé àti iṣan pèsè fún gbogbo ara, ti a ń so ó ṣọ̀kan pọ̀, ó ń dàgbà nípa ìmísí Ọlọ́run.

ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni ó tàn yín jẹ ̀nàkọnà, nítorí ọjọ́ náà yóò , ṣe ìṣọ̀tẹ̀ kọ́ ṣẹlẹ̀, a fi ẹni ̀ṣẹ̀ hàn, í ṣe ọmọ ègbé. Òun yóò lòdì , yóò gbé ara rẹ̀ ga gbogbo ohun a ń Ọlọ́run tàbí a ń sìn, ibi yóò gbé ara rẹ̀ jókòó nínú tẹmpili Ọlọ́run, yóò pe ara rẹ̀ Ọlọ́run.

Exemplos de adoração

Jó adorou em meio ao sofrimento. Esdras adorou na restauração. Paulo e Silas adoraram na prisão — e Deus respondeu.

Nígbà náà ni Jobu dìde, ó fa aṣọ ìgúnwà rẹ̀ ya, ó orí rẹ̀ ó wólẹ̀ ó gbàdúrà ,

"ìhòhò mo ti inú ìyá mi jáde ,

ni ìhòhò èmi yóò tún padà lọ.

Olúwa fi fún ni, Olúwa gbà á lọ,

ìbùkún ni fún orúkọ Olúwa."

Pẹ̀ìyìn àti ọpẹ́ ni wọ́n kọrin Olúwa:

"Ó dára;

ìfẹ́ rẹ̀ Israẹli dúró títí láé."

Gbogbo àwọn ènìyàn fi ohùn ariwo ńlá yin Olúwa, nítorí a ti fi ìpìlẹ̀ ilé Olúwa lélẹ̀.

Báyìí, èmi, Nebukadnessari fi ọpẹ́, mo gbé Ọlọ́run ga, mo fi ògo fún ọba ̀run, nítorí gbogbo nǹkan ó ṣe dára, gbogbo ̀rẹ̀ tọ́. Gbogbo àwọn ń rìn ìgbéraga ni ó le rẹ̀ sílẹ̀.

"Ìwọ tóbi, Olúwa Olódùmarè! ẹni ó dàbí rẹ, Ọlọ́run kan lẹ́yìn rẹ̀, gẹ́gẹ́ gbogbo èyí àwa fi etí gbọ́.

"ẹni ó mọ́ bi Olúwa;

ẹlòmíràn ṣe ìwọ;

àpáta bi Ọlọ́run wa.

Nígbà náà ni àwọn ọmọ Lefi: Jeṣua, Kadmieli, Bani, Haṣbneiah, Ṣerebiah, Hodiah, Ṣebaniah àti Petahiah, "dìde fi ìyìn fún Olúwa Ọlọ́run yín, ó láé àti láéláé."

"Ìbùkún ni fún orúkọ rẹ ó ògo, ó di gbígbéga ju gbogbo ìbùkún àti ìyìn lọ.

igi ̀pọ̀tọ́ ko tilẹ̀ tanná,

èso nínú àjàrà;

igi olifi ko le so,

àwọn oko ko oúnjẹ ;

a agbo ẹran kúrò nínú agbo,

ọwọ́ ẹran ni ibùso mọ́,

síbẹ̀, èmi ó láyọ̀ nínú Olúwa,

èmi yóò máa yọ nínú Ọlọ́run ìgbàlà mi.

Nígbà náà ni ̀yin yóò , ̀yin yóò gbàdúrà mi, èmi yóò gbọ́ àdúrà yín.

súnmọ́ Ọlọ́run, òun ó súnmọ́ yín. wẹ ọwọ́ yín mọ́, ̀yin ẹlẹ́ṣẹ̀; ṣe ọkàn yín mímọ́, ̀yin oníyèméjì.

Seja o primeiro