Publicidade

1 Samuel 2

Àdúrà Hana

1 Hana gbàdúrà ,

"Ọkàn mi yọ̀ Olúwa;

ìwo agbára mi ni a gbé sókè Olúwa.

Ẹnu mi gbòòrò lórí àwọn ̀mi,

nítorí ti èmi yọ̀ ni ìgbàlà rẹ̀.

2 "ẹni ó mọ́ bi Olúwa;

ẹlòmíràn ṣe ìwọ;

àpáta bi Ọlọ́run wa.

3 "ṣe halẹ̀;

ṣe jẹ́ ìgbéraga ti ẹnu yín jáde

nítorí Ọlọ́run olùmọ̀ ni Olúwa,

láti ̀dọ̀ rẹ̀ ni a ti ń wọn ìwà.

4 "̀run àwọn alágbára ti ṣẹ́,

àwọn ó ṣe aláìlera ni a fi agbára àmùrè.

5 Àwọn ó yọ̀ fún oúnjẹ ti fi ara wọn ṣe alágbàṣe,

àwọn ebi ń pa ṣe aláìní.

bẹ́̀ àgàn fi méje.

Ẹni ó bímọ púpọ̀ di aláìlágbára.

6 "Olúwa pa ó sọ di ààyè;

ó sọ̀kalẹ̀ lọ isà òkú, ó gbé dìde.

7 Olúwa sọ di tálákà; ó sọ di ọlọ́rọ̀;

ó rẹ̀ sílẹ̀, ó gbé sókè.

8 Ó gbé tálákà sókè láti inú erùpẹ̀ ,

ó gbé alágbe sókè láti orí òkìtì eérú ,

láti wọn jókòó pẹ̀àwọn ọmọ-aládé,

láti mu wọn jogún ìtẹ́ ògo,

"Nítorí ̀wọ́n ayé ti Olúwa ni,

ó ti gbé ayé ka orí wọn.

9 Yóò pa ẹsẹ̀ àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ mọ́,

àwọn ènìyàn búburú ni yóò dákẹ́ òkùnkùn.

"Nípa agbára ọkùnrin yóò borí.

10 A ó fọ́ àwọn ̀Olúwa túútúú;

láti ̀run ni yóò sán àrá wọn;

Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ òpin ayé.

"Yóò fi agbára fún ọba rẹ̀,

yóò si gbé ìwo ẹni àmì òróró rẹ̀ sókè."

11 Elkana lọ Rama, ilé rẹ̀, ọmọ náà ń ṣe ìránṣẹ́ fún Olúwa níwájú Eli àlùfáà.

Àwọn ọmọ Eli búburú

12 Àwọn ọmọ Eli jẹ́ ọmọ Beliali; wọn mọ Olúwa. 13 Iṣẹ́ àwọn àlùfáà pẹ̀àwọn ènìyàn ni nígbà ẹnìkan ṣe ìrúbọ, ìránṣẹ́ àlùfáà á , nígbà ẹran náà ń lórí iná, pẹ̀̀pá-ẹran náà oníga mẹ́ta ọwọ́ rẹ̀. 14 Òun a fi gún inú apẹ, tàbí àgé tàbí ọpọ́n, tàbí ìkòkò, gbogbo èyí ̀pá-ẹran oníga náà òkè, àlùfáà á un fún ara rẹ̀. Bẹ́̀ ni wọ́n ń ṣe gbogbo Israẹli ó ibẹ̀ Ṣilo. 15 Pẹ̀, wọn sun ̀náà, ìránṣẹ́ àlùfáà á , á fún ọkùnrin ó ń ṣe ìrúbọ , "Fi ẹran fún mi láti sun fún àlùfáà; nítorí yóò gba ẹran sísè lọ́wọ́ rẹ, ṣe tútù."

16 ọkùnrin náà fún un , "Jẹ́ wọn ó sun ̀náà nísinsin yìí, o iyekíye ọkàn rẹ̀ fẹ́," nígbà náà ni yóò a lóhùn , "Bẹ́̀ kọ́, ṣùgbọ́n ìwọ ó fi í fún mi nísinsin yìí, ṣe bẹ́̀, èmi ó fi agbára gbà á."

17 ̀ṣẹ̀ àwọn ̀dọ́mọkùnrin náà tóbi gidigidi níwájú Olúwa: nítorí àwọn ènìyàn kórìíra ẹbọ Olúwa.

18 Ṣùgbọ́n Samuẹli ń ṣe ìránṣẹ́ níwájú Olúwa, ọmọdé, ti a wọ̀ efodu ̀gbọ̀. 19 Pẹ̀lúpẹ̀, ìyá rẹ̀ máa ń aṣọ ìlekè péńpé fún un, a máa fún un lọ́dọọdún, nígbà ó ọkọ rẹ̀ gòkè láti ṣe ìrúbọ ọdún. 20 Eli súre fún Elkana àti aya rẹ̀ , "Olúwa fún irú-ọmọ láti ara obìnrin yìí , nítorí ̀bùn ó béèrè ó tún fún Olúwa." Wọ́n lọ ilé wọn. 21 Olúwa si bojú wo Hana, ó lóyún, ó ọmọkùnrin mẹ́ta àti ọmọbìnrin méjì. Samuẹli ọmọ náà ń dàgbà níwájú Olúwa.

22 Eli di arúgbó gidigidi, ó gbọ́ gbogbo èyí ti àwọn ọmọ rẹ̀ ṣe gbogbo Israẹli; àti bi wọ́n ti máa ń àwọn obìnrin sùn, wọ́n máa ń péjọ ẹnu-ọ̀àgọ́ àjọ. 23 Ó fún wọn , ni ó ti ri "Èétirí èmi fi ń gbọ́ irú nǹkan bẹ́̀ yín? Nítorí èmi ń gbọ́ iṣẹ́ búburú yín láti ̀dọ̀ gbogbo ènìyàn. 24 Bẹ́̀ kọ́ ̀yin ọmọ mi, nítorí ṣe ìròyìn rere èmi gbọ́; ̀yin ènìyàn Olúwa dẹ́ṣẹ̀. 25 ẹnìkan ṣẹ̀ ẹnìkejì, onídàájọ́ yóò ṣe ìdájọ́ rẹ̀: ṣùgbọ́n ẹnìkan ṣẹ̀ Olúwa, ta ni yóò bẹ̀bẹ̀ fún un?" Wọn fi etí ohùn baba wọn, nítorí Olúwa ń fẹ́ pa wọ́n.

26 Ọmọ náà Samuẹli ń dàgbà, ó ojúrere lọ́dọ̀ Olúwa, àti ènìyàn pẹ̀.

Wòlíì sọtẹ́lẹ̀ nípa ilé Eli

27 Ènìyàn Ọlọ́run kan tọ Eli , ó fún un , "Báyìí ni Olúwa , Èmi fi ara mi hàn gbangba fún ilé baba rẹ, nígbà wọ́n ń bẹ Ejibiti nínú ilé Farao. 28 Èmi yàn án kúrò láàrín gbogbo ̀Israẹli láti jẹ́ àlùfáà mi, láti ẹbọ lórí pẹpẹ mi, láti fi tùràrí jóná, láti wọ efodu níwájú mi, èmi fi gbogbo ẹbọ ọmọ Israẹli máa ń fi iná sun fún ìdílé baba rẹ̀. 29 Èéha ṣe ̀yin fi tàpá ẹbọ àti ọrẹ mi, mo pàṣẹ ibùjókòó mi, ìwọ bu ọlá fún àwọn ọmọ rẹ lọ, fi gbogbo àṣàyàn ẹbọ Israẹli àwọn ènìyàn mi ara yín sanra.

30 "Nítorí náà Olúwa Ọlọ́run Israẹli , Èmi ti nítòótọ́ , ilé rẹ àti ilé baba rẹ, yóò máa rìn níwájú mi títí.Ṣùgbọ́n nísinsin yìí Olúwa , á i! Àwọn ó ọlá fún mi ni èmi yóò bu ọlá fún, àti àwọn ni a ó ṣe aláìkàsí. 31 Kíyèsi i, àwọn ọjọ́ ń bọ̀ èmi ó agbára rẹ kúrò, àti agbára baba rẹ, yóò arúgbó kan nínú ilé rẹ. 32 Ìwọ yóò wàhálà ti Àgọ́, nínú gbogbo ọlá Ọlọ́run yóò fi fún Israẹli; yóò arúgbó kan nínú ilé rẹ láéláé. 33 Ọkùnrin ó jẹ́ tìrẹ, èmi yóò kúrò ibi pẹpẹ mi ni a ó láti sọkún yọ lójú àti láti banújẹ́. Ṣùgbọ́n gbogbo irú-ọmọ ilé rẹ̀ ni a ó fi idà pa ààbọ̀ ọjọ́ wọn.

34 " ni ohun ó ṣẹlẹ̀ àwọn ọmọ ọkùnrin rẹ̀ méjèèjì, Hofini àti Finehasi, yóò jẹ́ àmì fún àwọn méjèèjì yóò ọjọ́ kan náà. 35 Èmi yóò dìde fún ara mi láti gbé àlùfáà olódodo dìde fún ara mi, ẹni yóò ṣe gẹ́gẹ́ ohun ó ọkàn mi àti inú mi. Èmi yóò fi ẹsẹ̀ ilé rẹ̀ múlẹ̀ gbọningbọnin òun yóò ṣe òjíṣẹ́ níwájú ẹni òróró mi ọjọ́ gbogbo. 36 Nígbà náà olúkúlùkù ẹnikẹ́ni ó ìdílé yín, yóò jáde yóò foríbalẹ̀ níwájú rẹ̀ nítorí ẹyọ fàdákà àti nítorí èépá àkàrà àti ̀bẹ̀ , "Jọ̀wọ́ yàn ̀kan nínú iṣẹ́ àwọn àlùfáà, èmi ó le máa oúnjẹ jẹ." ’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-