Publicidade

Jó 1

Ìbẹ̀rẹ̀ ìgbé ayé Jobu

1 Ọkùnrin kan ilẹ̀ Usi, orúkọ ẹni í jẹ́ Jobu; ọkùnrin náà ṣe olóòtítọ́, ó dúró ṣinṣin, ẹni ó bẹ̀Ọlọ́run, ó kórìíra ìwà búburú. 2 A bi ọmọkùnrin méje àti ọmọbìnrin mẹ́ta fún un. 3 Ohun ̀sìn rẹ̀ jẹ́ ̀́dẹ́gbàárin (7,000) àgùntàn, àti ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) ìbákasẹ, àti ̀́dẹ́gbẹ̀ta (500) àjàgà ̀màlúù, àti ̀́dẹ́gbẹ̀ta (500) abo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ó pọ̀; bẹ́̀ ni ọkùnrin yìí pọ̀gbogbo àwọn ará ìlà-oòrùn lọ.

4 Àwọn ọmọ rẹ̀ a máa lọ í jẹun àsè nínú ilé ara wọn, olúkúlùkù ọjọ́ rẹ̀; wọn a máa ránṣẹ́ arábìnrin wọn mẹ́tẹ̀̀ta láti jẹun àti láti pẹ̀wọn. 5 Ó ṣe, nígbà ọjọ́ àsè wọn yíká, ni Jobu ránṣẹ́ lọ í wọ́n mímọ́, ó dìde kùtùkùtù òwúrọ̀, ó ẹbọ sísun níwọ̀n iye gbogbo wọn; nítorí Jobu : bóyá àwọn ọmọ mi ti ṣẹ̀, wọn ṣọpẹ́ fún Ọlọ́run lọ́kàn wọn. Bẹ́̀ Jobu máa ń ṣe nígbà gbogbo.

Ìdánwò Jobu àkọ́kọ́

6 Ǹjẹ́ ó di ọjọ́ kan, nígbà àwọn ọmọ Ọlọ́run í níwájú Olúwa, Satani pẹ̀wọn. 7 Olúwa bi Satani , "Níbo ni ìwọ ti ?"

Nígbà náà Satani Olúwa lóhùn , "ìlọsíwá-sẹ́yìn lórí ilẹ̀ ayé, àti ìrìnkèrindò nínú rẹ̀."

8 Olúwa sọ fún Satani , "Ìwọ ha kíyèsi Jobu ìránṣẹ́ mi, ẹni ó dàbí rẹ̀ ayé, ọkùnrin í ṣe olóòtítọ́, ó dúró ṣinṣin, ẹni ó bẹ̀Ọlọ́run, ti ó kórìíra ìwà búburú."

9 Nígbà náà ni Satani Olúwa lóhùn , "Jobu ha bẹ̀Ọlọ́run asán ?" 10 "Ìwọ ha ti ṣọgbà yìí , àti ilé rẹ̀ àti ohun ó , ìhà gbogbo? Ìwọ bùsi iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀, ohun ̀sìn rẹ̀ ń pọ̀ si ilẹ̀. 11 Ǹjẹ́, nawọ́ rẹ nísinsin yìí, ó fi tọ́ ohun gbogbo ó ni; yóò bọ́hùn ni ojú rẹ."

12 Olúwa Satani lóhùn , "Kíyèsi i, ohun gbogbo ó ń bẹ ìkáwọ́ rẹ, kìkì òun tìkára rẹ̀ ni ìwọ gbọdọ̀ fi ọwọ́ rẹ kàn."

Bẹ́̀ ni Satani jáde lọ kúrò níwájú Olúwa.

13 Ó di ọjọ́ kan nígbà àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin àti obìnrin, wọ́n mu ọtí wáìnì nínú ilé ̀gbọ́n wọn ọkùnrin, 14 oníṣẹ́ kan tọ Jobu , "Àwọn ̀màlúù ń tulẹ̀, àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ń jẹ ̀gbẹ́ wọn, 15 àwọn ará Sabeani kọlù wọ́n, wọ́n ń wọn lọ pẹ̀, wọ́n ti fi idà àwọn ìránṣẹ́ pa, èmi nìkan ṣoṣo ó àsálà láti ròyìn fún ."

16 ó ti ń sọ ẹnu; ẹnìkan pẹ̀ó , "Iná ńlá Ọlọ́run ti ̀run bọ́ ilẹ̀, ó àwọn àgùntàn àti àwọn ìránṣẹ́; èmi nìkan ṣoṣo ó sálà láti ròyìn fún ."

17 ó ti ń sọ ẹnu, ẹnìkan pẹ̀ó , "Àwọn ará Kaldea píngun ̀mẹ́ta, wọ́n kọlù àwọn ìbákasẹ, wọ́n wọn lọ, pẹ̀lúpẹ̀wọ́n fi idà àwọn ìránṣẹ́ pa; èmi nìkan ṣoṣo ni ó àsálà láti ròyìn fún !"

18 ó ti ń sọ ẹnu, ẹnìkan pẹ̀ó àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin àti obìnrin ń jẹ, wọ́n ń mu ọtí wáìnì nínú ilé ̀gbọ́n. 19 kíyèsi i, ̀fúùfù ńlá ńlá ti ìhà ijù fẹ́ kọlu igun mẹ́rẹ̀̀rin ilé, ó lu àwọn ̀dọ́mọkùnrin náà, wọ́n , èmi nìkan ṣoṣo ni ó yọ láti ròyìn fún .

20 Nígbà náà ni Jobu dìde, ó fa aṣọ ìgúnwà rẹ̀ ya, ó orí rẹ̀ ó wólẹ̀ ó gbàdúrà 21 ,

"ìhòhò mo ti inú ìyá mi jáde ,

ni ìhòhò èmi yóò tún padà lọ.

Olúwa fi fún ni, Olúwa gbà á lọ,

ìbùkún ni fún orúkọ Olúwa."

22 Nínú gbogbo èyí Jobu ṣẹ̀, bẹ́̀ ni fi òmùgọ̀ pe Ọlọ́run lẹ́jọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-