Publicidade

Salmos 68

Fún adarí orin. Ti Dafidi. Saamu. Orin.

1 Ọlọ́run ó dìde, àwọn ̀rẹ̀ ó fọ́nká;

àwọn ̀rẹ̀ ó níwájú rẹ̀.

2 ìjì ti ń fẹ́ èéfín lọ,

ó fẹ́ wọn lọ;

ìda ti í yọ́ níwájú iná,

olùṣe búburú ṣègbé níwájú Ọlọ́run.

3 Ṣùgbọ́n inú olódodo ó dùn

ó kún fún ayọ̀ níwájú Ọlọ́run;

inú wọn ó dùn, ó kún fún ayọ̀.

4 kọrin Ọlọ́run,

kọrin ìyìn i,

la ̀fún ẹni ń rékọjá aginjù.

Olúwa ni orúkọ rẹ̀, máa yọ̀ níwájú rẹ̀.

5 Baba àwọn aláìní baba àti onídàájọ́ àwọn opó ni Ọlọ́run ibùgbé

rẹ̀ mímọ́

6 Ọlọ́run gbé aláìlera

kalẹ̀ nínú ìdílé,

ó darí àwọn ẹlẹ́wọ̀n pẹ̀orin,

ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́tẹ̀ ń gbé nínú ilẹ̀ gbígbẹ.

7 Nígbà ìwọ jáde lónìí níwájú àwọn ènìyàn rẹ, Ọlọ́run,

ń kọjá lọ láàrín aginjù, Sela.

8 Ilẹ̀ títí,

àwọn ̀run ń rọ òjò jáde,

níwájú Ọlọ́run,

ẹni Sinai,

níwájú Ọlọ́run, Ọlọ́run Israẹli.

9 Ìwọ fún wa ̀pọ̀lọpọ̀ òjò, Ọlọ́run;

ìwọ tu ilẹ̀ ìní rẹ̀ lára nígbà ó rẹ̀ ́ tan.

10 Àwọn ènìyàn rẹ tẹ̀síbẹ̀

nínú ̀pọ̀lọpọ̀ ìní rẹ, Ọlọ́run, ìwọ pèsè fún àwọn aláìní.

11 Olúwa ti pàṣẹ ̀rọ̀,

púpọ̀ ogun àwọn ẹni ó ń ròyìn rẹ̀.

12 "Àwọn ọba àti àwọn ológun yára sálọ;

obìnrin ó jókòó ni ilé ń pín ìkógun náà.

13 Nígbà ̀yin dùbúlẹ̀ láàrín agbo ẹran,

nígbà náà ni ̀yin ó dàbí ìyẹ́ àdàbà ti a fàdákà,

àti ìyẹ́ rẹ̀ pẹ̀wúrà pupa."

14 Nígbà Olódùmarè fọ́n àwọn ọba ilẹ̀ náà,

ó dàbí òjò dídi Salmoni.

15 Òkè Baṣani jẹ́ òkè Ọlọ́run;

òkè ó orí púpọ̀ ni òkè Baṣani.

16 ̀yin fi ń ṣe ìlara,

̀yin òkè wúwo, òkè Ọlọ́run ti fẹ́ láti jẹ ọba

níbi Olúwa fúnra rẹ̀ yóò máa gbé títí láé?

17 Ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ni kẹ̀kẹ́ ogun Ọlọ́run

ẹgbẹ̀rún lọ́ẹgbẹ̀rún;

Olúwa ń bẹ láàrín wọn, Sinai ni ibi mímọ́ rẹ̀.

18 Ìwọ ti gòkè ibi gíga

ìwọ ti di ìgbèkùn ìgbèkùn lọ;

ìwọ ti gba ̀bùn fún ènìyàn:

nítòótọ́, fún àwọn ọlọ̀tẹ̀ pẹ̀,

Olúwa Ọlọ́run máa wọn gbé.

19 Olùbùkún ni Olúwa,

Ọlọ́run Olùgbàlà wa,

ẹni ó ń fi ojoojúmọ́ gba ẹrù wa . Sela.

20 Ọlọ́run wa jẹ́ Ọlọ́run ń gbàlà

àti Olúwa Olódùmarè ni ó ń gbà lọ́wọ́ ikú.

21 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run yóò tẹ orí àwọn ̀rẹ̀,

àti agbárí onírun àwọn ń tẹ̀síwájú nínú ̀ṣẹ̀ wọn

22 Olúwa , "Èmi ó wọn láti Baṣani;

èmi ó wọn láti ibú omi Òkun,

23 ẹsẹ̀ rẹ ó le pọ́n inú ̀jẹ̀ àwọn ̀rẹ,

àti ahọ́n àwọn ajá rẹ ìpín tiwọn lára àwọn ̀rẹ."

24 Wọ́n ti ìrìn rẹ, Ọlọ́run,

ìrìn Ọlọ́run mi àti ọba mi ibi mímọ́ rẹ̀.

25 Àwọn akọrin iwájú, àwọn olórin lẹ́yìn;

àwọn ọmọbìnrin ń lu ṣaworo pẹ̀wọn.

26 fi ìyìn fún Olúwa ẹgbẹgbẹ́;

àní fún Olúwa ̀yin ó ti orísun Israẹli .

27 Níbẹ̀ ̀kékeré Benjamini , ó ń darí wọn,

níbẹ̀ ni àwọn ọmọ-aládé Juda,

níbẹ̀ ni àwọn ọmọ-aládé Sebuluni àti Naftali.

28 Pàṣẹ agbára rẹ, Ọlọ́run;

fi agbára rẹ hàn , Ọlọ́run, gẹ́gẹ́ ìwọ ti ṣe ìṣáájú.

29 Nítorí tẹmpili rẹ ni Jerusalẹmu

àwọn ọba yóò ̀bùn fún .

30 àwọn ẹranko búburú ,

ń gbé láàrín eèsún

̀pọ̀lọpọ̀ àwọn akọ màlúù

pẹ̀àwọn ọmọ màlúù

títí olúkúlùkù yóò fi foríbalẹ̀ pẹ̀ìwọ̀n fàdákà:

àwọn ènìyàn ń ṣe inú dídùn ogun .

31 Àwọn ọmọ-aládé yóò láti Ejibiti;

Etiopia yóò na ọwọ́ rẹ̀ Ọlọ́run.

32 Kọrin Ọlọ́run, ̀yin ìjọba ayé,

kọrin ìyìn Olúwa, Sela.

33 ẹni ń gun ̀run ̀run àtijọ́ lókè,

ń fọhùn rẹ̀, ohùn ńlá.

34 Kéde agbára Ọlọ́run,

ọláńlá rẹ̀ lórí Israẹli,

agbára rẹ̀ lójú ̀run.

35 Ìwọ ̀, Ọlọ́run, ibi mímọ́ rẹ;

Ọlọ́run Israẹli fi agbára àti okun fún àwọn ènìyàn rẹ.

Olùbùkún Ọlọ́run!

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-