Publicidade

Salmos 143

Saamu ti Dafidi.

1 Olúwa gbọ́ àdúrà mi,

fetísí igbe mi fún àánú;

nínú òtítọ́ àti òdodo rẹ, fún ìrànlọ́wọ́ mi.

2 ṣe ìránṣẹ́ rẹ ìdájọ́,

nítorí ẹnìkan ó láààyè

ó ṣe òdodo níwájú rẹ.

3 ̀ń lépa mi,

ó fún mi pamọ́ ilẹ̀;

ó mi gbé nínú òkùnkùn

àwọn ó ti ti pẹ́.

4 Nítorí náà ̀mi ṣe rẹ̀wẹ̀nínú mi;

ọkàn mi nínú mi ṣì pòruurù.

5 Èmi rántí ọjọ́ ó ti pẹ́;

èmi ń ṣe àṣàrò lórí gbogbo iṣẹ́ rẹ

mo ṣe àkíyèsí ohun ọwọ́ rẹ ti ṣe.

6 Èmi na ọwọ́ mi jáde :

òǹgbẹ rẹ gbẹ ọkàn mi i ìyàngbẹ ilẹ̀. Sela.

7 mi lóhùn kánkán, Olúwa;

ó rẹ ̀mi tán.

ṣe pa ojú rẹ mọ́ kúrò lára mi

èmi ba à dàbí àwọn ó lọ sínú ihò.

8 mi gbọ́ ìṣeun ìfẹ́ rẹ òwúrọ̀:

nítorí ìwọ ni mo gbẹ́kẹ̀.

Fi ̀èmi i rìn hàn ,

nítorí èmi gbé ọkàn mi sókè .

9 Gbà kúrò lọ́wọ́ àwọn ̀mi, Olúwa,

nítorí èmi fi ara mi pamọ́ sínú rẹ.

10 Kọ́ mi láti ṣe ìfẹ́ rẹ,

nítorí ìwọ ni Ọlọ́run mi

jẹ́ ̀rẹ dídára

darí mi ilẹ̀ ó tẹ́.

11 Nítorí orúkọ rẹ, Olúwa, sọ mi di ààyè;

nínú òdodo rẹ, ọkàn mi jáde nínú wàhálà.

12 Nínú ìfẹ́ rẹ í kùnà, àwọn ̀mi kúrò,

run gbogbo àwọn ń ni ọkàn mi lára,

nítorí èmi ni ìránṣẹ́ rẹ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-