Pular para o conteúdo
Publicidade

Salmos 99

1 Olúwa jẹ ọba;

jẹ́ ayé ó wárìrì

Ó jókòó lórí ìtẹ́ kérúbù

jẹ́ ayé ó wárìrì.

2 Olúwa tóbi Sioni;

Ó ga gbogbo orílẹ̀-èdè lọ.

3 wọ́n yin orúkọ rẹ̀ ó tóbi

ó ni ̀, Mímọ́ ni Òun.

4 Ọba náà agbára, ó fẹ́ òdodo,

ìwọ fi ìdí àìṣègbè múlẹ̀;

ìwọ ṣe ohun ó tọ́ àti ohun ó yẹ nínú Jakọbu.

5 Gbígbéga ni Olúwa Ọlọ́run wa

foríbalẹ̀ níbi ẹsẹ̀ rẹ̀; ó jẹ́ mímọ́.

6 Mose àti Aaroni nínú àwọn àlùfáà rẹ̀

Samuẹli nínú àwọn ó ń pe orúkọ rẹ̀

wọ́n pe Olúwa, ó wọn lóhùn.

7 Ó sọ̀rọ̀ wọn nínú ̀wọ́n àwọsánmọ̀,

wọ́n pa ̀rẹ̀ mọ́ àti ìlànà ó fún wọn.

8 Olúwa Ọlọ́run wa, ó wọn lóhùn;

ó jẹ́ Ọlọ́run ó ń dáríjì àwọn ọmọ Israẹli

ìwọ ó ń fi ìyà àìṣedéédéé wọn jẹ wọ́n.

9 Gbígbéga ni Olúwa Ọlọ́run wa

a sìn ín òkè mímọ́ rẹ̀

nítorí Olúwa Ọlọ́run wa jẹ́ mímọ́.

Veja também