Pular para o conteúdo
Publicidade

Salmos 29

Saamu ti Dafidi.

1 fi fún Olúwa, ̀yin ̀̀run,

fi fún Olúwa, ògo àti alágbára.

2 Fi fún Olúwa, àní ògo orúkọ rẹ̀;

sin Olúwa nínú ẹwà ìwà mímọ́.

3 Ohùn Olúwa n àwọn omi kọjá;

Ọlọ́run ògo sán àrá,

Olúwa san ara.

4 Ohùn Olúwa agbára;

ohùn Olúwa kún fún ọláńlá.

5 Ohùn Olúwa fa igi kedari;

Olúwa náà fọ́ igi kedari Lebanoni ya.

6 Ó Lebanoni fo i ọmọ màlúù,

àti Sirioni ọmọ àgbáǹréré.

7 Ohùn Olúwa ń ya

ọwọ́ iná mọ̀.

8 Ohùn Olúwa ń mi aginjù.

Olúwa mi aginjù Kadeṣi.

9 Ohùn Olúwa ó lọ igi óákù, ó n abo àgbọ̀nrín ,

ó bọ́ igi igbó ìhòhò.

Àti nínú tẹmpili rẹ̀ gbogbo ohùn , "Ògo!"

10 Olúwa jókòó, Ó jẹ ọba lórí ìṣàn omi;

Olúwa jókòó lórí ìtẹ́ gẹ́gẹ́ Ọba títí láéláé.

11 Olúwa fi agbára fún àwọn ènìyàn rẹ̀;

bùkún àwọn ènìyàn rẹ̀ pẹ̀àlàáfíà.

Veja também