Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuel 1

10 Pẹ̀̀dùn ọkàn Hana sọkún gidigidi, ó gbàdúrà Olúwa. 11 Ó jẹ́ ̀jẹ́ , "Olúwa àwọn ọmọ-ogun, jùlọ ìwọ le bojú wo ìránṣẹ́bìnrin rẹ ìwọ rántí rẹ̀, ìwọ gbàgbé ìránṣẹ́ rẹ ṣùgbọ́n ìwọ yóò fún un ọmọkùnrin, nígbà náà èmi yóò fi fún Olúwa gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀ a yóò fi abẹ kàn án orí."

12 ó ṣe ń gbàdúrà Olúwa, Eli kíyèsi ẹnu rẹ̀. 13 Hana ń gbàdúrà láti inú ọkàn rẹ̀, ṣùgbọ́n ètè rẹ̀ ni ó ń , a gbọ́ ohùn rẹ̀. Eli ó ti mu ọtí . 14 Eli fún un , "Yóò ti pẹ́ fún ìwọ yóò máa ? ọtí wáìnì rẹ̀ kúrò."

15 Hana a lóhùn , "Bẹ́̀ kọ́, Olúwa mi, èmi ni obìnrin oníròbìnújẹ́. Èmi mu ọtí wáìnì tàbí ọtí líle; èmi ń ọkàn mi jáde Olúwa ni. 16 ṣe ìránṣẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ obìnrin búburú. Èmi ti ń gbàdúrà níhìn-ín nínú ìrora ọkàn àti ìbànújẹ́ mi."

17 Eli dáhùn , "Máa lọ àlàáfíà, Ọlọ́run Israẹli fi ohun ìwọ ti béèrè ọwọ́ rẹ̀ fún ."

18 Ó , "ìránṣẹ́bìnrin rẹ oore-ọ̀fẹ́ lójú rẹ." Bẹ́̀ ni obìnrin náà tirẹ̀ lọ, ó jẹun, fa ojú ro mọ́.

19 Wọ́n dìde ni kùtùkùtù òwúrọ̀, wọn wólẹ̀ sìn níwájú Olúwa, wọn padà wa ilé wọn ni Rama: Elkana si mọ Hana aya rẹ̀: Olúwa rántí rẹ̀. 20 Ó ṣe, nígbà ọjọ́ rẹ̀ , lẹ́yìn ìgbà Hana lóyún, ó ọmọkùnrin kan, ó pe orúkọ rẹ̀ Samuẹli, , "Nítorí mo béèrè rẹ̀ lọ́wọ́ Olúwa."Olúwa

Veja também