Publicidade

1 Samuel 1

Ìbí Samuẹli

1 Ọkùnrin kan , láti Ramataimu-Sofimu, láti ìlú olókè Efraimu, ẹni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Elkana, ọmọ Jerohamu, ọmọ Elihu, ọmọ Tohu, ọmọ Sufu, ará Efrata. 2 Ó ìyàwó méjì, orúkọ wọn ni Hana àti Penina: Penina ọmọ, ṣùgbọ́n Hana .

3 ọdọọdún, ọkùnrin yìí máa ń gòkè láti ìlú rẹ̀ láti lọ sìn àti láti ṣe ìrúbọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun jùlọ Ṣilo, níbi àwọn ọmọkùnrin Eli méjèèjì, Hofini àti Finehasi ti jẹ́ àlùfáà Olúwa. 4 Nígbàkígbà ó kan Elkana láti ṣe ìrúbọ, òun yóò lára ẹran fún aya rẹ̀ Penina àti fún gbogbo àwọn ọmọ ọkùnrin àti obìnrin. 5 Ṣùgbọ́n ó máa ń pín ìlọ́po fun Hana nítorí ó fẹ́ràn rẹ̀ àti Olúwa ti e nínú. 6 Nítorí Olúwa ti e nínú, orogún rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ fín níràn láti ó bínú. 7 Eléyìí máa ń ṣẹlẹ̀ ọdọọdún. Nígbàkígbà Hana gòkè lọ ilé Olúwa, orogún rẹ̀ a máa fín níràn títí yóò fi máa sọkún jẹun. 8 Elkana ọkọ rẹ̀ yóò sọ fún un , "Hana èéṣe ìwọ fi ń sọkún? Èéṣe ìwọ fi jẹun? Èéṣe ìwọ fi ń ba ọkàn jẹ́? Èmi ha ju ọmọ mẹ́wàá lọ fún ?"

9 Lẹ́yìn ìgbà wọ́n ti jẹ, wọ́n tún mu tán Ṣilo, Hana dìde síwájú Olúwa. Nígbà náà, Eli àlùfáà lórí àga ̀gbẹ́ ẹnu-ọ̀ilé Olúwa ibi ó máa ń jókòó. 10 Pẹ̀̀dùn ọkàn Hana sọkún gidigidi, ó gbàdúrà Olúwa. 11 Ó jẹ́ ̀jẹ́ , "Olúwa àwọn ọmọ-ogun, jùlọ ìwọ le bojú wo ìránṣẹ́bìnrin rẹ ìwọ rántí rẹ̀, ìwọ gbàgbé ìránṣẹ́ rẹ ṣùgbọ́n ìwọ yóò fún un ọmọkùnrin, nígbà náà èmi yóò fi fún Olúwa gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀ a yóò fi abẹ kàn án orí."

12 ó ṣe ń gbàdúrà Olúwa, Eli kíyèsi ẹnu rẹ̀. 13 Hana ń gbàdúrà láti inú ọkàn rẹ̀, ṣùgbọ́n ètè rẹ̀ ni ó ń , a gbọ́ ohùn rẹ̀. Eli ó ti mu ọtí . 14 Eli fún un , "Yóò ti pẹ́ fún ìwọ yóò máa ? ọtí wáìnì rẹ̀ kúrò."

15 Hana a lóhùn , "Bẹ́̀ kọ́, Olúwa mi, èmi ni obìnrin oníròbìnújẹ́. Èmi mu ọtí wáìnì tàbí ọtí líle; èmi ń ọkàn mi jáde Olúwa ni. 16 ṣe ìránṣẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ obìnrin búburú. Èmi ti ń gbàdúrà níhìn-ín nínú ìrora ọkàn àti ìbànújẹ́ mi."

17 Eli dáhùn , "Máa lọ àlàáfíà, Ọlọ́run Israẹli fi ohun ìwọ ti béèrè ọwọ́ rẹ̀ fún ."

18 Ó , "ìránṣẹ́bìnrin rẹ oore-ọ̀fẹ́ lójú rẹ." Bẹ́̀ ni obìnrin náà tirẹ̀ lọ, ó jẹun, fa ojú ro mọ́.

19 Wọ́n dìde ni kùtùkùtù òwúrọ̀, wọn wólẹ̀ sìn níwájú Olúwa, wọn padà wa ilé wọn ni Rama: Elkana si mọ Hana aya rẹ̀: Olúwa rántí rẹ̀. 20 Ó ṣe, nígbà ọjọ́ rẹ̀ , lẹ́yìn ìgbà Hana lóyún, ó ọmọkùnrin kan, ó pe orúkọ rẹ̀ Samuẹli, , "Nítorí mo béèrè rẹ̀ lọ́wọ́ Olúwa."

A ya Samuẹli mímọ́ fún Olúwa

21 Ọkùnrin náà Elkana, àti gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀, gòkè lọ láti ẹbọ ọdún Olúwa, àti láti sán ̀jẹ́ rẹ̀. 22 Ṣùgbọ́n Hana gòkè lọ; nítorí ó sọ fún ọkọ rẹ̀ , "Ó di ìgbà mo gba ọmú lẹ́nu ọmọ náà, nígbà náà ni èmi yóò un lọ, òun fi ara hàn níwájú Olúwa, ó máa gbé ibẹ̀ títí láé."

23 Elkana ọkọ rẹ̀ fún un , "Ṣe èyí ó tọ́ lójú rẹ. Dúró títí ìwọ yóò fi gba ọmú lẹ́nu rẹ̀; ṣùgbọ́n Olúwa à ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ." Bẹ́̀ ni obìnrin náà jókòó, ó fi ọmú fún ọmọ rẹ̀ títí ó fi gbà á lẹ́nu rẹ̀.

24 Nígbà ó gba ọmú lẹ́nu rẹ̀, ó un gòkè lọ pẹ̀ara rẹ̀. Pẹ̀ẹgbọrọ màlúù mẹ́ta, àti ìyẹ̀fun efa kan, àti ìgò ọtí wáìnì kan, ó un ilé Olúwa Ṣilo: ọmọ náà ọmọdé. 25 Wọ́n pa ẹgbọrọ màlúù, wọ́n ọmọ náà tọ Eli . 26 Hana , "Olúwa mi, ọkàn rẹ ti láààyè, Olúwa mi, èmi ni obìnrin náà ó dúró lẹ́bàá ̀dọ̀ rẹ níhìn-ín ń tọrọ lọ́dọ̀ Olúwa. 27 Ọmọ yìí ni mo ń tọrọ; Olúwa fi ìdáhùn ìbéèrè mo béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀ fún mi. 28 Nítorí náà pẹ̀, èmi fi í fún Olúwa; gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀: nítorí mo ti béèrè rẹ̀ fún Olúwa." Wọn si wólẹ̀ sin Olúwa níbẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-