Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuẹli 1

22 Ṣùgbọ́n Hana gòkè lọ; nítorí ó sọ fún ọkọ rẹ̀ , "Ó di ìgbà mo gba ọmú lẹ́nu ọmọ náà, nígbà náà ni èmi yóò un lọ, òun fi ara hàn níwájú Olúwa, ó máa gbé ibẹ̀ títí láé."

23 Elkana ọkọ rẹ̀ fún un , "Ṣe èyí ó tọ́ lójú rẹ. Dúró títí ìwọ yóò fi gba ọmú lẹ́nu rẹ̀; ṣùgbọ́n Olúwa à ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ." Bẹ́̀ ni obìnrin náà jókòó, ó fi ọmú fún ọmọ rẹ̀ títí ó fi gbà á lẹ́nu rẹ̀.

24 Nígbà ó gba ọmú lẹ́nu rẹ̀, ó un gòkè lọ pẹ̀ara rẹ̀. Pẹ̀ẹgbọrọ màlúù mẹ́ta, àti ìyẹ̀fun efa kan, àti ìgò ọtí wáìnì kan, ó un ilé Olúwa Ṣilo: ọmọ náà ọmọdé.

Veja também