Publicidade

1 Samuel 18

Saulu ń jowú Dafidi

1 Lẹ́yìn ìgbà Dafidi ti parí ̀rọ̀ ó ń Saulu sọ, ọkàn Jonatani di ̀kan pẹ̀ti Dafidi, ó fẹ́ràn rẹ̀ gẹ́gẹ́ ara rẹ̀. 2 Láti ọjọ́ náà Saulu pa Dafidi mọ́ ̀dọ̀ rẹ̀ jẹ́ ó padà ilé baba rẹ̀ mọ́. 3 Jonatani Dafidi májẹ̀nítorí ó fẹ́ràn rẹ̀ gẹ́gẹ́ ara rẹ̀. 4 Jonatani bọ́ aṣọ ìgúnwà, ó fi fun Dafidi pẹ̀aṣọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ rẹ̀ àti pẹ̀idà rẹ̀, ọrun rẹ̀ àti àmùrè rẹ̀.

5 Ohunkóhun Saulu rán an láti ṣe, Dafidi máa ṣe àṣeyọrí, Saulu náà fun un ipò ó ga láàrín àwọn ológun. Eléyìí tẹ́ gbogbo ènìyàn lọ́rùn, àti pẹ̀ó tẹ́ àwọn ìjòyè Saulu lọ́rùn pẹ̀.

6 Nígbà àwọn ènìyàn padà ilé lẹ́yìn ìgbà Dafidi ti pa Filistini, gbogbo àwọn obìnrin jáde láti inú ìlú Israẹli láti pàdé ọba Saulu pẹ̀orin àti ijó, pẹ̀orin ayọ̀ àti tambori àti ohun èlò orin olókùn. 7 wọ́n ṣe ń , bẹ́̀ ni wọ́n ń kọrin ,

"Saulu pa ẹgbẹ̀rún tirẹ̀

Dafidi pa ẹgbẹẹgbàárún tirẹ̀."

8 Saulu bínú gidigidi, ̀rọ̀ náà korò létí rẹ̀ , "Wọ́n ti gbé ògo fún Dafidi pẹ̀ẹgbẹẹgbàárún," ó , "ṣùgbọ́n èmi pẹ̀ẹgbẹ̀rún kan. ni ó ó gbà ṣe ìjọba?" 9 Láti ìgbà náà lọ ni Saulu ti bẹ̀rẹ̀ fi ojú ìlara wo Dafidi.

10 ọjọ́ kejì ̀búburú láti ̀dọ̀ Ọlọ́run pẹ̀agbára sórí Saulu, ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ ilé rẹ̀ nígbà Dafidi ń fọn ohun èlò orin olókùn, gẹ́gẹ́ ó ti máa ń ṣe láti ̀yìn , Saulu ̀kọ̀ kan ọwọ́ rẹ̀. 11 Ó gbé e sókè, ó fún ara rẹ̀ , "Èmi yóò gún Dafidi pọ̀ mọ́ ògiri." Ṣùgbọ́n, Dafidi yẹ̀ fún un lẹ́̀méjì.

12 Saulu ń bẹ̀Dafidi nítorí Olúwa pẹ̀Dafidi, ṣùgbọ́n ó ti fi Saulu sílẹ̀. 13 Ó Dafidi jáde ̀dọ̀ rẹ̀, ó fi jẹ olórí ogun ẹgbẹ̀rún kan (1,000), Dafidi ń wọn lọ, ó ń wọn bọ̀ nínú ìgbòkègbodò ogun. 14 Dafidi ṣe ọlọ́gbọ́n gbogbo ìṣe rẹ̀, nítorí Olúwa pẹ̀rẹ̀. 15 Nígbà Saulu bi àṣeyọrí rẹ̀ ti , ó bẹ̀rẹ̀. 16 Ṣùgbọ́n gbogbo Israẹli àti Juda ni wọ́n fẹ́ràn Dafidi, nítorí ó darí wọn lọ ìgbòkègbodò ogun wọn.

17 Saulu fún Dafidi , "Èyí ni àgbà nínú àwọn ọmọbìnrin mi Merabu. Èmi yóò fi òun fún aya. ìwọ sìn akọni, o máa ja ogun Olúwa." Nítorí Saulu fún ara rẹ̀ , "Èmi yóò gbé ọwọ́ mi sókè i. Jẹ́ àwọn Filistini ṣe èyí."

18 Ṣùgbọ́n Dafidi fún Saulu , "Ta ni , ni ìdílé mi tàbí ìdílé baba mi Israẹli, èmi yóò di àna ọba?" 19 Nígbà àkókò fún Merabu, ọmọbìnrin Saulu, láti fi fún Dafidi, ni a fi fún Adrieli ará Mehola aya.

20 Nísinsin yìí ọmọbìnrin Saulu Mikali fẹ́ràn Dafidi, nígbà wọ́n sọ fún Saulu nípa rẹ̀, ó dùn mọ́ ọn. 21 Ó sọ nínú ara rẹ̀ , "Èmi yóò fi fún un òun ba à le jẹ́ ìkẹ́kùn fún un, ọwọ́ àwọn ará Filistini lára rẹ̀." Nígbà náà ni Saulu fún Dafidi , "Nísinsin yìí ìwọ àǹfààní eléyìí láti jẹ́ àna án mi."

22 Saulu pàṣẹ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ , "sọ fún Dafidi ìkọ̀kọ̀, , ó, inú ọba dùn , gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ni ó fẹ́ràn rẹ, nísinsin yìí jẹ́ àna ọba.’ "

23 Wọ́n tún ̀rọ̀ náà sọ fún Dafidi. Ṣùgbọ́n Dafidi , "Ṣé ohun kékeré ni láti jẹ́ àna ọba? Mo jẹ́ tálákà ènìyàn àti onímọ̀ kékeré."

24 Nígbà àwọn ìránṣẹ́ Saulu sọ fún un ohun Dafidi sọ, 25 Saulu dáhùn , "Sọ fún Dafidi , Ọba fẹ́ owó orí láti ̀dọ̀ àna rẹ̀ ju awọ iwájú orí ọgọ́rùn-ún Filistini lọ láti fi gba ̀san lórí àwọn ̀rẹ̀.’ " Èrò Saulu ni Dafidi ṣubú ọwọ́ àwọn ará Filistini.

26 Nígbà àwọn ìránṣẹ́ sọ àwọn nǹkan yìí fún Dafidi, inú rẹ̀ dùn láti di àna ọba àkókò ó kọjá, 27 Dafidi àti àwọn arákùnrin rẹ̀ jáde lọ wọ́n pa igba lára àwọn Filistini. Ó awọ iwájú orí wọn , ó iye ọba fẹ́ ó ba à jẹ́ àna ọba. Saulu fi ọmọ obìnrin Mikali fún un aya.

28 Nígbà Saulu mọ̀ Olúwa pẹ̀Dafidi ọmọbìnrin rẹ̀ Mikali fẹ́ràn Dafidi, 29 Saulu tún bẹ̀Dafidi síwájú àti síwájú, Saulu di ̀Dafidi fún gbogbo ọjọ́ rẹ̀ tókù.

30 Àwọn ọmọ-aládé Filistini tún tẹ̀síwájú láti lọ ogun, ó ṣe lẹ́yìn ìgbà wọ́n lọ, Dafidi ṣe àṣeyọrí ju gbogbo àwọn ìránṣẹ́ Saulu lọ, orúkọ rẹ̀ gbilẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-