Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuel 25

Dafidi, Nabali àti Abigaili

1 Samuẹli ; gbogbo ènìyàn Israẹli ara wọn jọ, wọ́n sọkún rẹ̀ wọ́n sin ín nínú ilé rẹ̀ Rama. Dafidi dìde, ó sọ̀kalẹ̀ lọ ijù Parani.

2 Ọkùnrin kan ń bẹ Maoni, ẹni iṣẹ́ rẹ̀ ń bẹ Karmeli; ọkùnrin náà ọrọ̀ púpọ̀, ó ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) àgùntàn, àti ẹgbẹ̀rún (1,000) ewúrẹ́: ó ń rẹ irun àgùntàn rẹ̀ Karmeli. 3 Orúkọ ọkùnrin náà ń jẹ́ Nabali, orúkọ aya rẹ̀ ń jẹ́ Abigaili; òun jẹ́ olóye obìnrin, àti arẹwà ènìyàn; ṣùgbọ́n òǹrorò àti oníwà búburú ni ọkùnrin; ẹni ìdílé Kalebu ni òun jẹ́.

4 Dafidi gbọ́ aginjù Nabali ń rẹ́ irun àgùntàn rẹ̀. 5 Dafidi rán ọmọkùnrin mẹ́wàá, Dafidi sọ fún àwọn ̀dọ́kùnrin náà , "gòkè lọ Karmeli, tọ Nabali lọ, i ni orúkọ mi. 6 Báyìí ni ó fún ẹni ó ni ìrora , Àlàáfíà fún ! Àlàáfíà fún ohun gbogbo ìwọ !

7 " Ǹjẹ́ mo gbọ́ , àwọn olùrẹ́run ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ. ó, àwọn olùṣọ́-àgùntàn rẹ ti lọ́dọ̀ wa àwa pa wọ́n lára, wọn sọ ohunkóhun gbogbo ọjọ́ wọ́n Karmeli. 8 Bi àwọn ọmọkùnrin rẹ léèrè, wọn ó sọ fún . Nítorí náà, jẹ́ àwọn ọmọkùnrin wọ̀nyí ojúrere lọ́dọ̀ rẹ; nítorí àwa ọjọ́ àsè: èmi bẹ̀ ́ ohunkóhun ọwọ́ rẹ , fi fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ, àti fún Dafidi ọmọ rẹ.’ "

9 Àwọn ọmọkùnrin Dafidi lọ, wọ́n sọ fún Nabali gẹ́gẹ́ gbogbo ̀rọ̀ wọ̀nyí orúkọ Dafidi, wọ́n sinmi.

10 Nabali àwọn ìránṣẹ́ Dafidi lóhùn , "Ta ni ń jẹ́ Dafidi? Tàbí ta ni ń jẹ́ ọmọ Jese? ̀pọ̀lọpọ̀ ìránṣẹ́ ni ń bẹ ni ìsinsin yìí wọn olúkúlùkù kúrò lọ́dọ̀ olúwa rẹ̀. 11 Ǹjẹ́ ki èmi o oúnjẹ mi, àti omi mi, àti ẹran mi ti mo pa fún àwọn olùrẹ́run mi, ki èmi fi fún àwọn ọkùnrin ti èmi mọ̀ ibi wọ́n ti ?"

12 Bẹ́̀ ni àwọn ọmọkùnrin Dafidi ̀wọn pọ̀n, wọ́n padà, wọ́n , wọn si fún un gẹ́gẹ́ bi gbogbo ̀rọ̀ wọ̀nyí. 13 Dafidi fún àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ , "olúkúlùkù yín ó di idà rẹ́ mọ́ ìdí," olúkúlùkù ọkùnrin di idà tirẹ̀ mọ́ ìdí; àti Dafidi pẹ̀di idà tirẹ̀; ìwọ̀n irinwó (400) ọmọkùnrin si gòkè tọ Dafidi lẹ́yìn; igba si jókòó níbi ẹrù.

14 ̀kan nínú àwọn ọmọkùnrin Nabali si fún Abigaili aya rẹ̀ , "Wo o, Dafidi rán oníṣẹ́ láti aginjù láti olúwa wa; ó kanra mọ́ wọn. 15 Ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin náà ṣe oore fún wa gidigidi, wọn ṣe ibi kan, ohunkóhun ni ọwọ́ wa ni gbogbo ọjọ́ ti àwa wọn rìn nígbà ti àwa ń bẹ lóko. 16 Odi ni wọ́n à jásí fún wa lọ́sàn án, àti lóru, ni gbogbo ọjọ́ ti a fi wọn gbé, a n bojútó àwọn àgùntàn. 17 Ǹjẹ́, ó , ìwọ mọ èyí ti ìwọ yóò ṣe; nítorí a ti gbèrò ibi olúwa wa, àti gbogbo ilé rẹ̀; òun jásí ọmọ Beliali a le sọ̀rọ̀ fún."

18 Abigaili yára, ó igbá ìṣù àkàrà àti ìgò ọtí wáìnì méjì, àti àgùntàn márùn-ún, a ti ṣè, àti òsùwọ̀n àgbàdo yíyan márùn-ún, àti ọgọ́rùn-ún ìdì àjàrà, àti igba àkàrà èso ̀pọ̀tọ́, ó dìwọ́n ru kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́. 19 Òun fún àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ , "Máa lọ níwájú mi; ó, èmi ń bọ̀ lẹ́yìn yín," ṣùgbọ́n òun fún Nabali baálé rẹ̀.

20 o ti gun orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ó ń sọ̀kalẹ̀ ibi ìkọ̀kọ̀ òkè náà, ó, Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ níwájú rẹ̀; òun pàdé wọn. 21 Dafidi ti , "Ǹjẹ́ lásán ni èmi ti pa gbogbo èyí i ṣe ti eléyìí aginjù, ti ohunkóhun nínú gbogbo èyí ti í ṣe tirẹ̀: òun ni ó fi ibi san ìre fún mi yìí. 22 Bẹ́̀ àti bẹ́̀ lọ, ni ki Ọlọ́run ó ṣe àwọn ̀Dafidi, bi èmi fi ọkùnrin kan sílẹ̀ nínú gbogbo èyí i ṣe tirẹ̀ títí di ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀."

23 Abigaili Dafidi, ó yára, ó sọ̀kalẹ̀ lórí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ó dojúbolẹ̀ níwájú Dafidi, ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀. 24 Ó wólẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ̀, ó , "Olúwa mi, fi ̀ṣẹ̀ yìí mi: ó jẹ́ ìránṣẹ́bìnrin rẹ, èmi bẹ̀ ́, sọ̀rọ̀ létí rẹ, ó gbọ́ ̀rọ̀ ìránṣẹ́bìnrin rẹ. 25 Olúwa mi, èmi bẹ̀ ́ ka ọkùnrin Beliali yìí , àní Nabali. Nítorí orúkọ rẹ̀ ti jẹ́ bẹ́̀ ni òun náà . Nabali ni orúkọ rẹ̀, àìmoye si pẹ̀rẹ̀; ṣùgbọ́n èmi ìránṣẹ́bìnrin rẹ ri àwọn ọmọkùnrin olúwa mi, ti ìwọ rán. 26 Ǹjẹ́ olúwa mi, bi Olúwa ti láààyè, àti ̀rẹ̀ si ti láààyè, bi Olúwa ti dúró láti ta ̀jẹ̀ sílẹ̀, àti láti fi ọwọ́ ara rẹ gba ̀san; ǹjẹ́, àwọn ̀rẹ, àti àwọn ẹni ń gbèrò ibi olúwa mi bi i Nabali. 27 Ǹjẹ́ èyí ni ̀bùn ìránṣẹ́bìnrin rẹ fún olúwa mi, jẹ́ a fi fún àwọn ọmọkùnrin ti ń tọ olúwa mi lẹ́yìn.

28 "Èmi bẹ̀ ́, fi ìrékọjá arábìnrin rẹ jìn ín, nítorí Olúwa yóò ṣe ilé òdodo fún olúwa mi, nítorí ó ja ogun Olúwa. Nítorí náà a ri ibi kan ni ọwọ́ rẹ níwọ̀n ìgbà ó láààyè. 29 ọkùnrin kan dìde láti máa lépa rẹ, àti máa ̀rẹ, a ó di ̀olúwa mi nínú ìdì ìyè lọ́dọ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ; àti ̀àwọn ̀rẹ ni a ó gbọ̀n sọnù gẹ́gẹ́ kànnàkànnà jáde. 30 Yóò ṣe, Olúwa yóò ṣe olúwa mi gẹ́gẹ́ gbogbo ìre ó ti nípa tirẹ̀, yóò yàn ́ ni aláṣẹ lórí Israẹli. 31 Èyí yóò jásí ìbànújẹ́ fún , tàbí ìbànújẹ́ ọkàn fún olúwa mi, nítorí ìwọ ta ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀, tàbí olúwa mi gba ̀san fún ara rẹ̀, ṣùgbọ́n nígbà Olúwa ba ṣe oore fún olúwa mi, ǹjẹ́ rántí ìránṣẹ́bìnrin rẹ!"

32 Dafidi fún Abigaili , "Alábùkún fún ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ó rán lónìí yìí láti pàdé mi. 33 Ìbùkún ni fún ọgbọ́n rẹ, alábùkún ni ìwọ, ó da mi dúró lónìí yìí láti ta ̀jẹ̀ sílẹ̀, àti láti fi ọwọ́ mi gba ̀san fún ara mi. 34 Nítòótọ́, Olúwa Ọlọ́run Israẹli ń bẹ, ó da mi dúró láti pa ́ lára ṣe ìwọ ti yára ó pàdé mi, nítòótọ́ fún Nabali di ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀ nínú àwọn ọkùnrin rẹ̀."

35 Bẹ́̀ ni Dafidi gba nǹkan ó fún un lọ́wọ́ rẹ̀, ó fún un , "Gòkè lọ ni àlàáfíà ilé rẹ, ó, èmi ti gbọ́ ohùn rẹ, inú mi dùn ."

36 Abigaili tọ Nabali , ó, òun ṣe àsè ni ilé rẹ̀ gẹ́gẹ́ àsè ọba: inú Nabali dùn nítorí , ó ti ọtí ni àmupara; òun si sọ nǹkan fún un, díẹ̀ tàbí púpọ̀: títí di ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀ 37 Ó ṣe; ni òwúrọ̀, nígbà ti ọtí náà si tán lójú Nabali, obìnrin rẹ̀ ro nǹkan wọ̀nyí fún un, ọkàn rẹ nínú rẹ̀, òun dàbí òkúta. 38 Ó ṣe lẹ́yìn ìwọ̀n ọjọ́ mẹ́wàá, Olúwa lu Nabali, ó .

39 Dafidi gbọ́ Nabali , ó , "Ìyìn ni fún Olúwa o gbèjà gígàn mi láti ọwọ́ Nabali , ó ìránṣẹ́ rẹ̀ dúró láti ṣe ibi: Olúwa ìkà Nabali orí òun tìkára rẹ̀."

Dafidi ránṣẹ́, ó ba Abigaili sọ̀rọ̀ láti un fi ṣe aya fún ara rẹ̀. 40 Àwọn ìránṣẹ́ Dafidi lọ sọ́dọ̀ Abigaili ni Karmeli, wọn sọ fún un , "Dafidi rán si láti mu ṣe aya rẹ̀."

41 Ó dìde, ó dojúbolẹ̀, ó , "ó, jẹ́ ìránṣẹ́bìnrin rẹ ó jẹ́ ìránṣẹ́ kan láti máa wẹ ẹsẹ̀ àwọn ìránṣẹ́ olúwa mi." 42 Abigaili yára, ó dìde, ó gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ márùn-ún tẹ̀e lẹ́yìn; òun tẹ̀àwọn ìránṣẹ́ Dafidi, o di aya rẹ̀. 43 Dafidi Ahinoamu ará Jesreeli; àwọn méjèèjì jẹ́ aya rẹ̀. 44 Ṣùgbọ́n Saulu ti fi Mikali ọmọ rẹ̀ obìnrin aya Dafidi, fún Palti ọmọ Laiṣi i ṣe ara Galimu.

Veja também