Publicidade

1 Samuel 3

Olúwa pe Samuẹli

1 Samuẹli ọmọkùnrin náà ṣe òjíṣẹ́ níwájú Olúwa abẹ́ Eli. ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì ̀rọ̀ Olúwa ṣọ̀wọ́n: ìran púpọ̀.

2 alẹ́ ọjọ́ kan Eli ẹni ojú rẹ̀ ti bẹ̀rẹ̀ di aláìlágbára, ríran dáradára, ó dùbúlẹ̀ ipò rẹ̀ bi ti àtẹ̀yìnwá. 3 Nígbà iná ì Samuẹli dùbúlẹ̀ nínú tẹmpili Olúwa, níbi àpótí Olúwa gbé . 4 Nígbà náà ni Olúwa pe Samuẹli.

Samuẹli dáhùn, "Èmi nìyí." 5 Ó sáré lọ ̀dọ̀ Eli ó , "Èmi nìyí nítorí ìwọ ."

Ṣùgbọ́n Eli fún un , "Èmi ́; padà lọ dùbúlẹ̀." Nítorí náà ó lọ ó lọ dùbúlẹ̀.

6 Olúwa tún é, "Samuẹli!" Samuẹli tún dìde ó tọ Eli lọ, ó , "Èmi nìyìí, nítorí ìwọ ."

"Ọmọ mi, èmi ́, padà lọ dùbúlẹ̀."

7 àkókò yìí Samuẹli ì mọ̀ Olúwa: bẹ́̀ ni a ì fi ̀rọ̀ Olúwa hàn án.

8 Olúwa pe Samuẹli ìgbà kẹta, Samuẹli tún dìde, ó lọ sọ́dọ̀ Eli ó , "Èmi nìyìí; nítorí ìwọ ."

Nígbà náà ni Eli mọ̀ Olúwa ni ó ń pe ọmọ náà. 9 Nítorí náà Eli sọ fún Samuẹli, "Lọ o lọ dùbúlẹ̀. o ́, sọ , Máa , Olúwa nítorí ìránṣẹ́ rẹ ń gbọ́.’ " Bẹ́̀ ni Samuẹli lọ, ó lọ dùbúlẹ̀ ààyè rẹ̀.

10 Olúwa , ó dúró níbẹ̀, ó é ó ṣe é ìgbà ó kọjá, "Samuẹli! Samuẹli!"

Nígbà náà ni Samuẹli dáhùn , "Máa nítorí ìránṣẹ́ rẹ ń gbọ́."

11 Olúwa sọ fún Samuẹli , "ó, èmi ṣetán láti ṣe ohun kan Israẹli yóò jẹ́ etí gbogbo ènìyàn ó gbọ́ gooro. 12 ìgbà náà ni èmi yóò ohun gbogbo mo ti sọ ilé Eli ṣẹ láti ìbẹ̀rẹ̀ òpin. 13 Nítorí èmi sọ fún un , Èmi yóò ṣe ìdájọ́ fún ilé rẹ̀ títí láé nítorí ìwà ̀ṣẹ̀ wọn òun mọ̀ nípa rẹ̀ nítorí àwọn ọmọ rẹ̀ sọ ̀rọ̀-òdì, òun wọn lẹ́kun. 14 Nítorí náà, mo búra ilé Eli, Ìwà ̀ṣẹ̀ ilé Eli ni a yóò fi ẹbọ tàbí ọrẹ kúrò láéláé.’ "

15 Samuẹli dùbúlẹ̀ títí di òwúrọ̀ nígbà náà ó ṣí ìlẹ̀kùn ilé Olúwa, ó bẹ̀láti sọ ìran náà fún Eli. 16 Ṣùgbọ́n Eli é, ó , "Samuẹli, ọmọ mi."

Samuẹli dáhùn , "Èmi nìyìí."

17 Eli béèrè , "Kín ni ohun ó sọ fún ?" "ṣe fi pamọ́ fún mi. Ọlọ́run mi ṣe bẹ́̀ àti bẹ́̀ lọ pẹ̀, ìwọ fi ohunkóhun ó fún pamọ́ fún mi." 18 Samuẹli sọ gbogbo rẹ̀ fún un, fi ohun kankan pamọ́ fún un. Nígbà náà Eli , "Òun ni Olúwa; jẹ́ ó ṣe ohun ó dára ojú rẹ̀."

19 Olúwa pẹ̀Samuẹli ó ṣe ń dàgbà, jẹ́ ̀kan nínú ̀rọ̀ rẹ̀ kùnà. 20 Gbogbo Israẹli láti Dani títí Beerṣeba mọ̀ a ti fa Samuẹli kalẹ̀ gẹ́gẹ́ wòlíì Olúwa. 21 Olúwa bẹ̀rẹ̀ fi ara hàn án Ṣilo, nítorí Olúwa ti fi ará hàn án fún Samuẹli Ṣilo nípa ̀rọ̀ Olúwa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-