Publicidade

1 Samuel 4

1 ̀rọ̀ Samuẹli tọ gbogbo àwọn ọmọ Israẹli .

Àwọn Filistini gba àpótí ̀

Nísinsin yìí àwọn ọmọ Israẹli jáde láti lọ àwọn Filistini . Àwọn ọmọ Israẹli pàgọ́ Ebeneseri àti àwọn Filistini Afeki. 2 Àwọn Filistini ogun wọn sọ̀kalẹ̀ láti pàdé Israẹli, nígbà ogun náà bẹ̀rẹ̀, àwọn Filistini ṣẹ́gun Israẹli wọ́n pa ẹgbàajì (4,000) ọkùnrin nínú ogun náà. 3 Nígbà àwọn ọmọ-ogun náà padà ibùdó, àwọn àgbàgbà Israẹli béèrè , "Èéṣe ti Olúwa fi àwọn Filistini ṣẹ́gun wa lónìí? jẹ́ a gbé àpótí ̀Olúwa láti Ṣilo , ó ba à le lọ pẹ̀wa ó gbà kúrò lọ́wọ́ àwọn ̀wa."

4 Nítorí náà a rán àwọn ènìyàn lọ Ṣilo, wọ́n gbé àpótí ̀Olúwa àwọn ọmọ-ogun , ẹni ń láàrín àwọn Kérúbù àti àwọn ọmọ Eli méjèèjì Hofini àti Finehasi níbẹ̀ pẹ̀àpótí ̀Ọlọ́run.

5 Nígbà àpótí ̀Olúwa ibùdó, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli dìde láti kígbe bẹ́̀ ilẹ̀ tìtì. 6 ìgbà àwọn Filistini gbọ́ ariwo náà wọ́n béèrè , "ni gbogbo ariwo yìí ibùdó Heberu?"

Nígbà wọ́n mọ̀ àpótí ̀Olúwa ti ibùdó, 7 àwọn Filistini bẹ̀, Ọlọ́run kékeré ti wọ ibùdó, wọ́n , "A wọ wàhálà, irú èyí ì ṣẹlẹ̀ . 8 Àwa gbé! Ta ni yóò gbà kúrò lọ́wọ́ Ọlọ́run alágbára yìí? Àwọn ni Ọlọ́run ó fi ìpọ́njú pa àwọn ará Ejibiti pẹ̀gbogbo àjàkálẹ̀-ààrùn aginjù. 9 jẹ́ alágbára Filistini, ṣe ọkùnrin, bẹ́̀ kọ́, ̀yin yóò di ẹrú àwọn Heberu, wọ́n ti jẹ́ i yín. jẹ́ alágbára ọkùnrin, jagun!"

10 Nígbà náà àwọn Filistini , wọ́n ṣẹ́gun àwọn Israẹli olúkúlùkù padà sínú àgọ́ rẹ̀, wọ́n pa ̀pọ̀ ènìyàn, àwọn ará Israẹli ó ogun jẹ́ ẹgbàá mẹ́̀́dógún (30,000) àwọn ọmọ-ogun orí ilẹ̀. 11 Wọ́n gba àpótí ̀Olúwa, àwọn ọmọkùnrin Eli méjèèjì , Hofini àti Finehasi.

Ikú Eli

12 Lọ́jọ́ kan náà ará Benjamini kan láti ojú ogun ó lọ Ṣilo, aṣọ rẹ̀ fàya pẹ̀eruku lórí rẹ̀. 13 Nígbà ó , Eli jókòó sórí àga rẹ̀ ̀gbẹ́ ̀, ó ń , ọkàn rẹ̀ balẹ̀ nítorí àpótí ̀Olúwa. Nígbà ọkùnrin náà wọ ìlú ó sọ ohun ó ṣẹlẹ̀, gbogbo ìlú bẹ̀rẹ̀ sọkún.

14 Eli gbọ́ ìró ohùn ẹkún náà ó béèrè , "ni ìtumọ̀ ariwo yìí?"

Ọkùnrin náà sáré tọ Eli 15 Eli di ẹni méjìdínlọ́gọ́run (98) ọdún, ojú rẹ̀ di bàìbàì, ríran mọ́. 16 Ọkùnrin náà sọ fún Eli, "Mo ṣẹ̀ṣẹ̀ láti ibi ogun náà ni: mo láti ibi ogun náà lónìí."

Eli béèrè , "ni ó ṣẹlẹ̀ ọmọ mi?"

17 Ọkùnrin ó ìròyìn náà dáhùn , "Israẹli níwájú àwọn Filistini, ìṣubú àwọn ọmọ-ogun náà pọ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀ pẹ̀àwọn ọmọ rẹ méjèèjì, Hofini àti Finehasi, wọ́n , wọ́n ti gba àpótí ̀Olúwa lọ."

18 Nígbà ó dárúkọ àpótí ̀Olúwa, Eli ṣubú sẹ́yìn kúrò lórí àga ̀gbẹ́ bodè, ọrùn rẹ̀ ṣẹ́, ó , nítorí ó jẹ́ arúgbó ọkùnrin, ó tóbi, ó ti darí àwọn Israẹli fún ogójì ọdún.

19 Aya ọmọ rẹ̀, ìyàwó Finehasi, ó lóyún ó súnmọ́ àkókò àti . Nígbà ó gbọ́ ìròyìn náà wọ́n ti gba àpótí ̀Olúwa lọ àti baba ọkọ rẹ̀ àti ọkọ rẹ̀ ti , ó rọbí ó bímọ, ó borí ìrora ìrọbí náà. 20 ó ti ń lọ, obìnrin ó dúró í , "ṣe bẹ̀; nítorí o ti ọmọ ọkùnrin." Ṣùgbọ́n sọ̀rọ̀ tàbí kọ ibi ara i.

21 Ó pe ọmọ náà Ikabodu, , "ògo fún Israẹli mọ́," nítorí wọ́n ti gba àpótí ̀Ọlọ́run àti ikú baba ọkọ rẹ̀ àti ti ọkọ rẹ̀. 22 Ó si , "Ògo fún Israẹli mọ́, nítorí ti a ti gbá àpótí Ọlọ́run."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-