Publicidade

1 Samuel 5

6 Ọwọ́ Olúwa wúwo lára àwọn ènìyàn Aṣdodu àti gbogbo agbègbè rẹ̀: ó ìparun sórí wọn, ó pọ́n wọn lójú pẹ̀ààrùn oníkókó. 7 Nígbà àwọn ọkùnrin Aṣdodu ohun ó ṣẹlẹ̀, wọ́n , "Àpótí ̀Ọlọ́run ti Israẹli gbọdọ̀ dúró níbí yìí pẹ̀wa, nítorí ọwọ́ rẹ̀ wúwo lára wa àti lára Dagoni ọlọ́run ." 8 Nígbà náà ni wọ́n gbogbo àwọn olórí Filistini jọ wọ́n bi wọ́n , "ni a ó ṣe pẹ̀àpótí ̀Ọlọ́run àwọn Israẹli?"

Wọ́n dáhùn , "jẹ́ á gbé àpótí ̀Ọlọ́run àwọn Israẹli lọ Gati." Wọ́n gbé àpótí ̀Ọlọ́run Israẹli.

9 Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà wọ́n ti gbé e, ọwọ́ Olúwa ìlú náà, ó jìnnìjìnnì wọn. Ó pọ́n àwọn ènìyàn ìlú náà lójú, ọmọdé àti àgbà, pẹ̀àjàkálẹ̀-ààrùn oníkókó. 10 Wọ́n gbé àpótí ̀Ọlọ́run lọ Ekroni.

àpótí ̀Ọlọ́run ṣe wọ Ekroni, àwọn ará Ekroni fi igbe ta , "Wọ́n ti gbé àpótí ̀Ọlọ́run Israẹli tọ̀ láti pa àti àwọn ènìyàn wa." 11 Nígbà náà ni wọ́n pe gbogbo àwọn olórí àwọn Filistini jọ wọ́n , "gbé àpótí ̀Ọlọ́run àwọn Israẹli lọ: jẹ́ ó padà ààyè rẹ̀, bẹ́̀ kọ́ yóò pa àti àwọn ènìyàn wa." Ikú ti jìnnìjìnnì àwọn ará ìlú, ọwọ́ Ọlọ́run wúwo lára wọn.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-