Publicidade

1 Samuel 5

Àpótí ̀Olúwa Aṣdodu àti Ekroni

1 Lẹ́yìn ìgbà àwọn Filistini ti gba àpótí ̀Ọlọ́run lọ, wọ́n gbé e láti Ebeneseri Aṣdodu. 2 Nígbà àwọn Filistini gbé àpótí Ọlọ́run náà lọ tẹmpili Dagoni, wọ́n gbé e kalẹ̀ ̀Dagoni. 3 Nígbà àwọn ará Aṣdodu òwúrọ̀ kùtùkùtù ọjọ́ kejì, Dagoni ṣubú, ó dojúbolẹ̀ níwájú àpótí Olúwa, wọ́n gbé Dagoni, wọ́n tún fi ààyè rẹ̀. 4 Ṣùgbọ́n òwúrọ̀ ọjọ́ kejì nígbà wọ́n dìde, Dagoni ṣì , ó ṣubú ó dojúbolẹ̀ níwájú àpótí ̀Olúwa. Orí àti ọwọ́ rẹ̀ ti kúrò, ó dùbúlẹ̀ orí ìloro ẹnu-ọ̀, ara rẹ̀ nìkan ni ó . 5 Ìdí nìyìí títí di òní ó fi jẹ́ àlùfáà Dagoni tàbí àwọn mìíràn ó wọ inú tẹmpili Dagoni Aṣdodu fi ń tẹ orí ìloro ẹnu-ọ̀.

6 Ọwọ́ Olúwa wúwo lára àwọn ènìyàn Aṣdodu àti gbogbo agbègbè rẹ̀: ó ìparun sórí wọn, ó pọ́n wọn lójú pẹ̀ààrùn oníkókó. 7 Nígbà àwọn ọkùnrin Aṣdodu ohun ó ṣẹlẹ̀, wọ́n , "Àpótí ̀Ọlọ́run ti Israẹli gbọdọ̀ dúró níbí yìí pẹ̀wa, nítorí ọwọ́ rẹ̀ wúwo lára wa àti lára Dagoni ọlọ́run ." 8 Nígbà náà ni wọ́n gbogbo àwọn olórí Filistini jọ wọ́n bi wọ́n , "ni a ó ṣe pẹ̀àpótí ̀Ọlọ́run àwọn Israẹli?"

Wọ́n dáhùn , "jẹ́ á gbé àpótí ̀Ọlọ́run àwọn Israẹli lọ Gati." Wọ́n gbé àpótí ̀Ọlọ́run Israẹli.

9 Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà wọ́n ti gbé e, ọwọ́ Olúwa ìlú náà, ó jìnnìjìnnì wọn. Ó pọ́n àwọn ènìyàn ìlú náà lójú, ọmọdé àti àgbà, pẹ̀àjàkálẹ̀-ààrùn oníkókó. 10 Wọ́n gbé àpótí ̀Ọlọ́run lọ Ekroni.

àpótí ̀Ọlọ́run ṣe wọ Ekroni, àwọn ará Ekroni fi igbe ta , "Wọ́n ti gbé àpótí ̀Ọlọ́run Israẹli tọ̀ láti pa àti àwọn ènìyàn wa." 11 Nígbà náà ni wọ́n pe gbogbo àwọn olórí àwọn Filistini jọ wọ́n , "gbé àpótí ̀Ọlọ́run àwọn Israẹli lọ: jẹ́ ó padà ààyè rẹ̀, bẹ́̀ kọ́ yóò pa àti àwọn ènìyàn wa." Ikú ti jìnnìjìnnì àwọn ará ìlú, ọwọ́ Ọlọ́run wúwo lára wọn. 12 Àwọn wọ́n pọ́n wọn lójú pẹ̀ààrùn oníkókó, ẹkún ìlú náà gòkè lọ ̀run.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-