Publicidade

1 Samuel 7

1 Nígbà náà àwọn ará Kiriati-Jearimu , wọ́n gbé àpótí ̀Olúwa. Wọ́n gbé e lọ ilé Abinadabu lórí òkè, wọ́n ya Eleasari ọmọ rẹ̀ mímọ́ láti ṣọ́ àpótí ̀Olúwa.

Samuẹli ṣẹ́gun àwọn ará Filistini Mispa

2 Ó jẹ́ ìgbà pípẹ́, ogún ọdún ni àpótí ̀Olúwa fi Kiriati-Jearimu. Gbogbo ilé Israẹli ṣọ̀fọ̀ wọ́n pohùnréré ẹkún Olúwa. 3 Samuẹli sọ fún gbogbo ilé Israẹli , "ń padà ̀dọ̀ Olúwa pẹ̀gbogbo ọkàn yín, yẹra kúrò lọ́dọ̀ ọlọ́run àjèjì àti Aṣtoreti fi ara yín fún Olúwa sin òun nìkan ṣoṣo, òun yóò gbà yín kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Filistini." 4 Nígbà náà ni àwọn ọmọ Israẹli yẹra fún Baali àti Aṣtoreti, wọ́n sin Olúwa nìkan ṣoṣo.

5 Nígbà náà ni, Samuẹli , "gbogbo àwọn ọmọ Israẹli jọ Mispa, èmi yóò bẹ̀bẹ̀ fún un yín lọ́dọ̀ Olúwa." 6 Nígbà wọ́n ti péjọpọ̀ Mispa, wọ́n pọn omi, wọ́n á sílẹ̀ níwájú Olúwa. ọjọ́ náà, wọ́n gbààwẹ̀, wọ́n jẹ́wọ́ , "Àwa ti ṣẹ̀ Olúwa." Samuẹli jẹ́ olórí àwọn ọmọ Israẹli Mispa.

7 Nígbà àwọn Filistini gbọ́ àwọn Israẹli ti péjọ Mispa, àwọn aláṣẹ Filistini gòkè láti kọlù wọ́n. Nígbà àwọn ọmọ Israẹli gbọ́ èyí, ̀wọ́n nítorí àwọn Filistini. 8 Wọ́n sọ fún Samuẹli , "ṣe dákẹ́ kíké pe Olúwa Ọlọ́run wa fún wa, é ó gbà kúrò lọ́wọ́ àwọn Filistini." 9 Nígbà náà ni Samuẹli ̀dọ́-àgùntàn ó jẹ́ ọmọ ọmú, ó fi ẹbọ sísun Olúwa. Ó pe Olúwa nítorí ilé Israẹli, Olúwa a lóhùn.

10 Nígbà Samuẹli ń ṣe ìrúbọ ẹbọ sísun, àwọn Filistini súnmọ́ tòsí láti Israẹli ja ogun. Ṣùgbọ́n ọjọ́ náà, Olúwa sán àrá ńlá lu àwọn Filistini, ó jìnnìjìnnì wọn, a wọn níwájú àwọn ọmọ Israẹli. 11 Àwọn ọkùnrin Israẹli jáde láti Mispa. Wọ́n ń lépa àwọn Filistini, wọ́n pa wọ́n àpá rìn títí abẹ́ Beti-Kari.

12 Samuẹli òkúta kan ó fi lélẹ̀ láàrín Mispa àti Ṣeni, ó pe orúkọ rẹ̀ Ebeneseri, , "Ibí ni Olúwa ràn lọ́wọ́ ." 13 Bẹ́̀ ni wọ́n ṣẹ́gun Filistini, wọn agbègbè àwọn ọmọ Israẹli mọ́.

gbogbo ìgbésí ayé Samuẹli, ọwọ́ Olúwa lòdì àwọn Filistini. 14 Àwọn ìlú láti Ekroni Gati àwọn Filistini ti gbà lọ́wọ́ Israẹli ni ó ti gbà padà fún Israẹli, ó gba gbogbo ilẹ̀ agbègbè rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ ìṣàkóso àwọn Filistini. Ìrẹ́pọ̀ láàrín Israẹli àti àwọn Amori.

15 Samuẹli tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́ adájọ́ lórí Israẹli. ọjọ́ ayé e rẹ̀. 16 Láti ọdún ọdún, ó lọ yíká láti Beteli Gilgali Mispa, ó ń ṣe ìdájọ́ Israẹli gbogbo ibi wọ̀nyí. 17 Ṣùgbọ́n ó máa ń padà ilé rẹ̀ Rama, níbí ilé rẹ̀ , ó túnṣe ìdájọ́ Israẹli níbẹ̀, ó kọ́ pẹpẹ kan síbẹ̀ fún Olúwa.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-