Publicidade

1 Samuel 9

Samuẹli fi òróró yan Saulu

1 Ará Benjamini kan , ẹni ó jẹ́ aláàánú ọlọ́rọ̀, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Kiṣi, ọmọ Abieli, ọmọ Serori, ọmọ Bekorati, ọmọ Afiah ti Benjamini. 2 Ó ọmọkùnrin kan à ń Saulu, ̀dọ́mọkùnrin ó yanjú, ó jẹ́ arẹwà, ẹni ẹwà ú lọ láàrín gbogbo àwọn ọmọ Israẹliláti èjìká rẹ̀ lọ òkè, ó ga ju gbogbo àwọn ènìyàn tókù lọ.

3 Nísinsin yìí àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ó jẹ́ ti Kiṣi baba Saulu sọnù. Nígbà náà, Kiṣi sọ fún Saulu ọmọ rẹ̀ , "̀kan nínú àwọn ìránṣẹ́ pẹ̀rẹ lọ láti àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà." 4 Bẹ́̀ ó kọjá láàrín àwọn ìlú olókè Efraimu, ó kọjá àyíká ilẹ̀ Ṣaliṣa, ṣùgbọ́n wọn wọn. Wọ́n kọjá lọ òpópó Ṣaalimu, ṣùgbọ́n àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ níbẹ̀. Nígbà náà, ó kọjá agbègbè Benjamini, wọn wọn.

5 Nígbà wọ́n agbègbè Sufu, Saulu sọ fún ìránṣẹ́ ó lọ́dọ̀ rẹ̀ , ", jẹ́ á padà sẹ́yìn, bẹ́̀ kọ́, baba mi yóò ìrònú rẹ̀ dúró nípa àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ yóò bẹ̀rẹ̀ àníyàn nípa wa."

6 Ṣùgbọ́n ìránṣẹ́ náà fún un èsì , "ó, inú ìlú yìí ọkùnrin ènìyàn Ọlọ́run kan ; ó jẹ́ ẹni wọ́n ń bu ọlá fún, àti gbogbo ohun ó sọ ó máa ń jẹ́ òtítọ́. Jẹ́ á lọ síbẹ̀ nísinsin yìí, bóyá yóò sọ fún ̀a yóò gbà."

7 Saulu sọ fún ìránṣẹ́ rẹ̀, "àwa lọ, kín ni àwa fún ọkùnrin náà? Oúnjẹ inú àpò wa ti tán. A ̀bùn láti lọ sọ́dọ̀ ènìyàn Ọlọ́run. ni a ?"

8 Ìránṣẹ́ a lóhùn lẹ́̀kan i. "ó," ó , "Mo ìdámẹ́rin ṣékélì fàdákà lọ́wọ́. Èmi yóò fún ènìyàn Ọlọ́run náà ó fi ̀hàn ." 9 (Tẹ́lẹ̀ Israẹli ọkùnrin kan lọ béèrè lọ́dọ̀ Ọlọ́run, yóò , ", jẹ́ a lọ ̀dọ̀ wòlíì náà," nítorí àwọn alásọtẹ́lẹ̀ ìsinsin yìí ni wọ́n ń wòlíì).

10 Saulu sọ fún ìránṣẹ́ rẹ̀ ó dára, "Jẹ́ a lọ." Wọ́n jáde lọ ìlú ènìyàn Ọlọ́run náà ń gbé.

11 wọ́n ṣe ń lọ orí òkè ìlú náà, wọ́n pàdé àwọn ̀dọ́mọbìnrin ó ń jáde í bọ̀ láti pọn omí. Wọ́n bi wọ́n, "Ṣé wòlíì náà níbí?"

12 "Ó ," wọ́n dáhùn. "Ó ń bẹ níwájú u yín, múra nísinsin yìí, ó ṣẹ̀ṣẹ̀ ̀dọ̀ wa lónìí ni, nítorí àwọn ènìyàn ẹbọ rírú ni ibi gíga. 13 Kété ti wọ ìlú, ó i ó lọ ibi gíga láti lọ jẹun. Àwọn ènìyàn bẹ̀rẹ̀ jẹun títí yóò fi . Torí ó gbọdọ̀ bùkún ẹbọ náà; lẹ́yìn náà, àwọn a yóò jẹun. Gòkè lọ nísinsin yìí, ó yẹ i àkókò yìí."

14 Wọ́n gòkè lọ ìlú náà, wọ́n ti ń wọlé, níbẹ̀ ni Samuẹli, ń bọ̀ ̀dọ̀ wọn ó ti ń lọ ibi gíga náà.

15 Olúwa ti sọ létí Samuẹli ọjọ́ kan Saulu ó , 16 "ìwòyí ̀la, èmi yóò ran ọmọkùnrin kan láti ilẹ̀ Benjamini. Fi òróró yàn án gẹ́gẹ́ olórí lórí àwọn ọmọ Israẹli, yóò gba àwọn ènìyàn mi kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Filistini. Mo ti bojú wo àwọn ènìyàn mi, nítorí igbe wọn ti ̀dọ̀ mi."

17 Nígbà Samuẹli fojúrí Saulu, Olúwa sọ fún un , "Èyí ni ọkùnrin mo sọ fún nípa rẹ̀, yóò darí àwọn ènìyàn mi."

18 Saulu súnmọ́ Samuẹli ẹnu-ọ̀ìlú, ó , "Sọ fún mi èmi ń bẹ̀ ́ níbo ni ilé wòlíì náà ."

19 Samuẹli dáhùn , "Èmi ni wòlíì náà. máa gòkè lọ ṣáájú mi, ibi gíga, ó mi jẹun lónìí. òwúrọ̀ ni èmi yóò jẹ́ lọ, gbogbo ohun ó ọkàn rẹ èmi yóò sọ fún . 20 Fún ti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ó sọnù fún ọjọ́ mẹ́ta sẹ́yìn, ṣe dààmú nípa wọ́n: a ti wọn. ta ni gbogbo ìfẹ́ Israẹli ? í ṣe ìwọ àti gbogbo ilé baba à rẹ."

21 Saulu dáhùn , "Ṣùgbọ́n èmi í ṣe ̀Benjamini? Kékeré nínú ̀Israẹli. Ìdílé mi ha rẹ̀yìn jùlọ nínú gbogbo ̀Benjamini? Èéṣì ti ṣe ìwọ sọ̀rọ̀ yìí mi?"

22 Nígbà náà ni Samuẹli Saulu pẹ̀ìránṣẹ́ rẹ̀ wọ inú gbọ̀ngán, ó wọn jókòó iwájú àwọn a wọn ọgbọ̀n. 23 Samuẹli sọ fún alásè , "ìpín ẹran mo fún , èyí mo sọ fún o sọ́tọ̀."

24 Alásè náà gbé ẹsẹ̀ náà pẹ̀ohun ó lórí i rẹ̀, ó gbé e síwájú Saulu. Samuẹli , "Èyí ni ohun a fi pamọ́ fún . Jẹ, nítorí a á sọ́tọ̀ fún , fún ìdí yìí, láti ìgbà mo ti , Mo àlejò a .’ " Saulu jẹun pẹ̀Samuẹli ọjọ́ náà.

25 Lẹ́yìn ìgbà wọn ti sọ̀kalẹ̀ láti ibí gíga náà inú ìlú, Samuẹli Saulu sọ̀rọ̀ lórí òrùlé ilé e rẹ̀. 26 Wọ́n dìde àfẹ̀mọ́júmọ́, ó pe Saulu sórí òrùlé , "Múra, èmi yóò rán lọ." Nígbà Saulu múra tán òun àti Samuẹli jọ jáde lọ síta. 27 wọ́n ti ń sọ̀kalẹ̀ lọ ìpẹ̀kun ìlú náà, Samuẹli fún Saulu , "Sọ fún ìránṣẹ́ náà ó máa lọ ṣáájú u wa," ìránṣẹ́ náà ṣe bẹ́̀, "Ṣùgbọ́n ìwọ ó dúró díẹ̀, èmi ó sọ ọrọ̀ láti ̀dọ̀ Ọlọ́run fún ."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-