Publicidade

2 Samuel 22

Orin ìyìn Dafidi

1 Dafidi kọ ̀rọ̀ orin yìí Olúwa ọjọ́ Olúwa gbà á kúrò lọ́wọ́ gbogbo àwọn ̀rẹ̀, àti kúrò lọ́wọ́ Saulu. 2 Ó ,

"Olúwa ni àpáta mi, àti Olùgbàlà mi;

3 Ọlọ́run mi, àpáta mi, nínú ẹni èmi ààbò,

àti ìwo ìgbàlà mi, ibi ìsádi gíga mi.

Àti ibi ìlùmọ̀ mi, Olùgbàlà mi;

ìwọ ni ó ti gbà kúrò lọ́wọ́ ìwà ipá.

4 "Èmi pe Olúwa, ó yẹ láti máa yìn,

ó gbà lọ́wọ́ àwọn ̀mi.

5 Nígbà ìbìlù ìrora ikú mi káàkiri;

àwọn ìṣàn ènìyàn búburú dẹ́rùbà .

6 ̀isà òkú mi káàkiri;

ìkẹ́kùn ikú dojúkọ .

7 "Nínú ìpọ́njú mi, èmi Olúwa,

èmi gbé ohùn mi sókè Ọlọ́run mi.

Ó gbóhùn mi láti tẹmpili rẹ̀

igbe wọ etí rẹ̀.

8 Ilẹ̀ , ó wárìrì;

ìpìlẹ̀ ̀run wárìrì,

ó , nítorí ó bínú.

9 Èéfín ti ihò imú rẹ̀ jáde ,

iná ajónirun ti ẹnu rẹ̀ jáde ,

̀yin iná jáde láti inú rẹ̀.

10 Ó tẹ orí ̀run ba pẹ̀, ó sọ̀kalẹ̀;

òkùnkùn biribiri ń bẹ àtẹ́lẹsẹ̀ rẹ̀.

11 Ó gun orí kérúbù, ó ,

a i lórí ìyẹ́ afẹ́fẹ́.

12 Ó fi òkùnkùn ṣe ibùjókòó ara rẹ̀, àti àgbájọ omi,

àní ìṣúdudu ìkùùkuu àwọ̀ sánmọ̀.

13 Nípasẹ̀ ìmọ́lẹ̀ iwájú rẹ̀

̀yín iná ràn.

14 Olúwa sán àrá láti ̀run ,

̀gá-ògo jùlọ fọhùn rẹ̀.

15 Ó ta ọfà, ó wọn ;

ó kọ mànàmànà, ó ṣẹ́ wọn.

16 Ìṣàn ibú òkun fi ara hàn,

ìpìlẹ̀ ayé fi ara hàn,

nípa ìbáwí Olúwa,

nípa fífún èémí ihò imú rẹ̀.

17 "Ó ránṣẹ́ láti òkè , ó mi;

ó jáde láti inú omi ńlá .

18 Ó gbà lọ́wọ́ ̀mi alágbára,

lọ́wọ́ àwọn ó kórìíra mi, nítorí wọ́n lágbára lọ.

19 Wọ́n láti borí mi lọ́jọ́ ìpọ́njú mi,

ṣùgbọ́n Olúwa ni aláfẹ̀yìntì mi.

20 Ó mi ààyè ńlá,

ó gbà mi, nítorí inú rẹ̀ dún mi.

21 "Olúwa sán án fún mi gẹ́gẹ́ òdodo mi;

ó san án fún mi gẹ́gẹ́ mímọ́ ọwọ́ mi.

22 Nítorí èmi pa ̀Olúwa mọ́,

èmi fi ìwà búburú yapa kúrò lọ́dọ̀ Ọlọ́run mi.

23 Nítorí gbogbo ìdájọ́ rẹ̀ ni ó níwájú mi;

àti ti òfin rẹ̀, èmi yapa kúrò nínú wọn.

24 Èmi nínú ìwà títọ́ í,

èmi pa ara mi mọ́ kúrò nínú ̀ṣẹ̀ mi.

25 Olúwa san fún mi gẹ́gẹ́ òdodo mi,

gẹ́gẹ́ ìwà mímọ́ mi níwájú rẹ̀.

26 "Fún aláàánú ni ìwọ ó fi ara rẹ̀ hàn ni aláàánú,

àti fún ẹni ìdúró ṣinṣin òdodo ni ìwọ ó fi ara rẹ hàn ìdúró ṣinṣin òdodo.

27 Fún onínú funfun ni ìwọ fi ara rẹ hàn funfun;

àti fún ẹni wíwọ́ ni ìwọ ó fi ara rẹ hàn wíwọ́.

28 Àwọn ènìyàn ó nínú ìyà ni ìwọ ó gbàlà;

ṣùgbọ́n ojú rẹ lára àwọn agbéraga, láti rẹ̀ wọ́n sílẹ̀.

29 Nítorí ìwọ ni ìmọ́lẹ̀ mi, Olúwa;

Olúwa yóò sọ òkùnkùn mi di ìmọ́lẹ̀.

30 Bẹ́̀ ni nítorí nípa rẹ̀ ni èmi ti la àárín ogun kọjá;

nípa Ọlọ́run mi èmi ti fo odi kan.

31 "Ọlọ́run yìí, pípé ni ̀rẹ̀;

̀rọ̀ Olúwa ni a ti dánwò.

Òun ni asà fún gbogbo àwọn ó gbẹ́kẹ̀e.

32 Nítorí ta ni Ọlọ́run, ṣe Olúwa?

Ta ni àpáta, ṣe Ọlọ́run wa.

33 Ọlọ́run alágbára ni ó fún mi agbára,

ó sọ ̀mi di títọ́.

34 Ó ṣe ẹsẹ̀ mi ẹsẹ̀ abo àgbọ̀nrín;

ó mi dúró ibi gíga mi.

35 Ó kọ́ ọwọ́ mi ogun jíjà;

bẹ́̀ apá mi fa ọrun idẹ.

36 Ìwọ ti fún mi asà ìgbàlà rẹ̀;

ìrẹ̀lẹ̀ rẹ̀ ti sọ di ńlá.

37 Ìwọ sọ ìtẹ̀lẹ̀ di ńlá abẹ́ mi;

bẹ́̀ ẹsẹ̀ mi fi yọ̀.

38 "Èmi ti lépa àwọn ̀mi, èmi ti run wọ́n,

èmi pẹ̀yìndà títí èmi fi run wọ́n.

39 Èmi ti pa wọ́n run, èmi ti fọ́ wọn,

wọn le dìde mọ́, wọ́n ṣubú lábẹ́ mi.

40 Ìwọ ti fi agbára àmùrè fún ìjà;

àwọn ó ti dìde mi ni ìwọ ti tẹ̀ lórí ba fún mi.

41 Ìwọ àwọn ̀mi pẹ̀yìndà fún mi,

èmi ó pa àwọn ó kórìíra mi run.

42 Wọ́n , ṣùgbọ́n ẹnìkan láti gbà wọ́n;

wọ́n wo Olúwa, ṣùgbọ́n àwọn lóhùn.

43 Nígbà náà ni èmi gún wọn wẹ́wẹ́ erùpẹ̀ ilẹ̀,

èmi tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀ ẹrẹ̀ ìta, èmi tẹ́ wọn gbọrọ.

44 "Ìwọ gbà kúrò lọ́wọ́ ìjà àwọn ènìyàn mi,

ìwọ pa mi mọ́ ki èmi ṣe olórí àwọn àjèjì orílẹ̀-èdè.

Àwọn ènìyàn èmi mọ̀ yóò máa sìn .

45 Àwọn àjèjì láti tẹríba fún mi;

wọ́n ti gbúròó mi, wọ́n á gbọ́ tèmi.

46 Àyà yóò àwọn àlejò,

wọ́n ó fi ìbẹ̀kúrò níbi kọ́lọ́fín wọn.

47 "Olúwa ń bẹ́; olùbùkún ni àpáta mi!

Gbígbéga ni Ọlọ́run àpáta ìgbàlà mi.

48 Ọlọ́run ni ẹni ń gbẹ̀san mi,

àti ẹni ń rẹ àwọn ènìyàn sílẹ̀ lábẹ́ mi.

49 Àti ẹni ó gbà kúrò lọ́wọ́ àwọn ̀mi.

Ìwọ gbé mi sókè ju àwọn ó kórìíra mi lọ;

ìwọ gbà kúrò lọ́wọ́ àwọn ọkùnrin oníwà ipá.

50 Nítorí náà èmi ó fi ọpẹ́ fún , Olúwa,

láàrín àwọn àjèjì orílẹ̀-èdè, èmi ó kọrin orúkọ rẹ.

51 "Òun ni ilé ìṣọ́ ìgbàlà fún ọba rẹ̀;

ó fi àánú hàn fún ẹni àmì òróró rẹ̀,

fún Dafidi, àti fún irú-ọmọ rẹ̀ títí láéláé."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-