Publicidade

2 Samuel 6

A gbé àpótí ̀Jerusalẹmu

1 6.1-11: 1Ki 13.1-14. Dafidi tún gbogbo àwọn akọni ọkùnrin Israẹli jọ, wọ́n jẹ́ ẹgbàá mẹ́̀́dógún (30,000). 2 Dafidi dìde, ó lọ àti gbogbo àwọn ènìyàn ń bẹ́ lọ́dọ̀ rẹ́, láti Baalahi Juda , láti àpótí ̀Ọlọ́run ibẹ̀ , èyí a ń pe orúkọ rẹ̀ orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun ó jókòó láàrín àwọn kérúbù. 3 Wọ́n gbé àpótí ̀Ọlọ́run náà gun kẹ̀kẹ́ tuntun kan, wọ́n un láti ilé Abinadabu , èyí ó Gibeah: Ussa àti Ahio, àwọn ọmọ Abinadabu ń kẹ̀kẹ́ tuntun náà. 4 Wọ́n un láti ilé Abinadabu jáde , ó Gibeah, pẹ̀àpótí ̀Ọlọ́run, Ahio ń rìn níwájú àpótí ̀náà. 5 Dafidi àti gbogbo ilé Israẹli ṣiré níwájú Olúwa lára gbogbo onírúurú ohun èlò orin a fi igi arère ṣe àti lára ìlù haapu, ara tambori, sisitirumu àti lára kimbali.

6 Nígbà wọ́n ilẹ̀ ìpakà Nakoni, Ussa na ọwọ́ rẹ̀ àpótí ̀Ọlọ́run, ó dìímú, nítorí màlúù kọsẹ̀. 7 Ìbínú Olúwa ru Ussa; Ọlọ́run pa á níbẹ̀ nítorí ìṣísẹ̀ rẹ̀; níbẹ̀ ni ó ̀àpótí ̀Ọlọ́run.

8 Inú Dafidi bàjẹ́ nítorí Olúwa Ussa kúrò, ó pe orúkọ ibẹ̀ Peresi-Usa títí ó fi di òní yìí.

9 Dafidi bẹ̀Olúwa ọjọ́ náà, ó , "Àpótí ̀Olúwa yóò ti ṣe tọ̀ ?" 10 Dafidi fẹ́ àpótí ̀Olúwa sọ́dọ̀ rẹ̀ ìlú Dafidi; ṣùgbọ́n Dafidi un ilé Obedi-Edomu ará Gitti. 11 Àpótí ̀Olúwa gbé ilé Obedi-Edomu ará Gitti oṣù mẹ́ta; Olúwa bùkún fún Obedi-Edomu, àti gbogbo ilé rẹ̀.

12 6.12-19: 1Ki 15.1–16.3. A fún Dafidi ọba , "Olúwa ti bùkún fún ilé Obedi-Edomu, àti gbogbo èyí í ṣe tirẹ̀, nítorí àpótí ̀Ọlọ́run." Dafidi lọ, ó àpótí ̀náà gòkè láti ilé Obedi-Edomu ìlú Dafidi pẹ̀ayọ̀. 13 Ó ṣe nígbà àwọn ènìyàn ó ru àpótí ̀Olúwa ṣí ẹsẹ̀ mẹ́, òun a fi màlúù àti ẹran àbọ́pa ẹbọ. 14 Dafidi fi gbogbo agbára rẹ̀ níwájú Olúwa; Dafidi wọ efodu ̀gbọ̀. 15 Bẹ́̀ ni Dafidi àti gbogbo ilé Israẹli gbé àpótí ̀Olúwa gòkè , pẹ̀ìhó ayọ̀, àti pẹ̀ìró ìpè.

16 àpótí ̀Olúwa ti wọ ìlú Dafidi ; Mikali ọmọbìnrin Saulu wo láti ojú fèrèsé, ó Dafidi ọba ń sókè ó ń níwájú Olúwa; òun kẹ́gàn rẹ̀ ọkàn rẹ̀.

17 Wọ́n àpótí ̀Olúwa náà , wọ́n gbé e kalẹ̀ sípò rẹ̀ láàrín àgọ́ náà Dafidi pa fún un. Dafidi ẹbọ sísun àti ẹbọ ìrẹ́pọ̀ níwájú Olúwa. 18 Dafidi parí ìṣe ẹbọ sísun àti ẹbọ ìrẹ́pọ̀ náà, ó súre fún àwọn ènìyàn náà orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun. 19 Ó pín fún gbogbo àwọn ènìyàn náà, àní fún gbogbo ̀pọ̀ ènìyàn Israẹli, àti ọkùnrin àti obìnrin; fún olúkúlùkù ìṣù àkàrà kan àti ekìrí ẹran kan, àti àkàrà díndín kan. Gbogbo àwọn ènìyàn náà túká lọ, olúkúlùkù ilé rẹ̀.

̀ṣẹ̀ Mikali

20 Dafidi yípadà láti súre fún àwọn ará ilé rẹ̀, Mikali ọmọbìnrin Saulu jáde láti pàdé Dafidi, ó , "Báwo ni ọba Israẹli ṣe ṣe ara rẹ̀ lógo bẹ́̀ lónìí, ó bọ́ ara rẹ̀ sílẹ̀ lónìí lójú àwọn ìránṣẹ́bìnrin àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ̀kan nínú àwọn ènìyàn lásán ń bọ́ra rẹ̀ sílẹ̀."

21 Dafidi fún Mikali , "Níwájú Olúwa ni, ẹni ó yàn fẹ́ ju baba rẹ lọ, àti ju gbogbo ìdílé rẹ lọ, láti fi èmi ṣe olórí àwọn ènìyàn Olúwa, àní lórí Israẹli, èmi ó súre níwájú Olúwa. 22 Èmi ó tún rẹ ara mi sílẹ̀ bẹ́̀ lọ, èmi ó ṣe aláìníyìn lójú ara mi, àti lójú àwọn ìránṣẹ́bìnrin náà ti ìwọ , lọ́dọ̀ wọn náà ni èmi ó ògo."

23 Mikali ọmọbìnrin Saulu ọmọ, títí o fi di ọjọ́ ikú rẹ̀ nítorí ó sọ̀rọ̀-òdì yìí Dafidi.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-