Pular para o conteúdo
Publicidade

Resultados da busca por "fé"

260 resultados encontrados

  1. Deuteronômio 23

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 23
    Mostrando versículos 2–12 de 25

    2Kí ọmọ àlè má ṣe wọ ìpéjọ Olúwa, pàápàá títí dé ìran kẹwàá.

    9Nígbà tí o bá dó ti àwọn ọ̀tá rẹ, pa gbogbo ohun àìmọ́ kúrò.

    12Sàmì sí ibìkan lóde àgọ́, níbi tí o lè máa lọ láti dẹ ara rẹ lára.

  2. Ezequiel 8

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 8
    Mostrando versículos 1–15 de 18

    1Ní ọjọ́ karùn-ún, oṣù kẹfà ọdún kẹfà bí mo ṣe jókòó nílé mi pẹ̀lú àwọn àgbàgbà Juda níwájú mi, ọwọ́ Olúwa Olódùmarè bà lé mi níbẹ̀.

    4Sì kíyèsi i, ògo Ọlọ́run Israẹli wà níbẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìran ti mo rí ni pẹ̀tẹ́lẹ̀.

    15Ó sọ fún mi pé, "Ṣé ìwọ rí báyìí, ọmọ ènìyàn? Ìwọ yóò tún rí ìríra tó ga jù èyí lọ."

  3. 1 Crônicas 12

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 12
    Mostrando versículos 11–26 de 40

    11Attai ẹlẹ́ẹ̀kẹfà, Elieli èkeje,

    13Jeremiah ẹlẹ́ẹ̀kẹwàá àti Makbannai ẹlẹ́ẹ̀kọkànlá.

    26àwọn ọkùnrin Lefi ẹgbàajì ó le ẹgbẹ̀ta (4,600),

  4. Provérbios 27

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 27
    Mostrando versículos 5–17 de 27

    5Ìbániwí gbangba sànju ìfẹ́ ìkọ̀kọ̀ lọ.

    16dídá a lẹ́kun dàbí ìgbà tí ènìyàn ń dá afẹ́fẹ́ lẹ́kuntàbí bí ẹni tí ó gbá òróró.

    17Bí irin tí ń pọ́n irin múbẹ́ẹ̀ ni ènìyàn kan ń pọ́n ẹlòmíràn mú.

  5. Gênesis 10

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 10
    Mostrando versículos 12–26 de 32

    12àti Resini, tí ó wà ní àárín Ninefe àti Kala, tí ó jẹ́ ìlú olókìkí.

    24Arfakṣadi sì bí Ṣela,Ṣela sì bí Eberi.

    26Joktani sì bíAlmodadi, Ṣelefi, Hasarmafeti, Jera.

  6. Salmos 12

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 12
    Mostrando versículos 3–8 de 8

    3Olúwa kí ó gé ètè èké wọnàti gbogbo ahọ́n ìfọ́nnu

    6Ọ̀rọ̀ Olúwa sì jẹ aláìlábùkù,gẹ́gẹ́ bí fàdákà tí a yọ́ nínú ìléru amọ̀,tí a sọ di mímọ́ nígbà méje.

    8Àwọn ènìyàn búburú ń rin ìrìn fáàrí kirinígbà tí wọn ń bọ̀wọ̀ fún òsì láàrín àwọn ènìyàn.

  7. 1 Coríntios 4

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 4
    Mostrando versículos 2–21 de 21

    2Òun kan náà tí ó tọ́ fún ìríjú, ni kí ó jẹ́ olóòtítọ́.

    104.10: 1Kọ 1.18; 2Kọ 11.19; 1Kọ 3.18; 2Kọ 13.9; 1Kọ 2.3.Àwa jẹ́ aṣiwèrè nítorí Kristi, ṣùgbọ́n ẹ̀yin jẹ́ ọlọ́gbọ́n nínú Kristi! Àwa jẹ́ aláìlera, ṣùgbọ́n ẹ̀yin jẹ́ alágbára! Ẹ̀yin jẹ́ ẹni àyẹ́sí, àwa jẹ ẹni ẹ̀gàn!

    214.21: 2Kọ 1.23.Èwo ni ẹ yàn? Kí ń wá sọ́dọ̀ yín pẹ̀lú pàṣán, tàbí ni ìfẹ́, àti ẹ̀mí tútù?

  8. Números 31

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 31
    Mostrando versículos 22–37 de 54

    22Kìkì i wúrà, fàdákà, idẹ, irin, idẹ àti òjé.

    34ọ̀kẹ́ mẹ́ta ó lé ẹgbẹ̀rin (61,000) kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́,

    37Tí ìdá ti Olúwa sì jẹ́ ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (675) àgùntàn;

  9. Atos 13

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 13
    Mostrando versículos 18–52 de 52

    1813.18: De 1.31.ní ìwọ̀n ìgbà ogójì ọdún ni ó fi mú sùúrù fún ìwà wọn ní ijù,

    39Nípa rẹ̀ ni a ń dá olúkúlùkù ẹni tí ó gbàgbọ́ láre kúrò nínú ohun gbogbo, tí a kò lè dá yín láre rẹ̀ nínú òfin Mose.

    52Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn si kún fún ayọ̀ àti fún Ẹ̀mí Mímọ́.

  10. Jeremias 36

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 36
    Mostrando versículos 8–15 de 32

    8Baruku ọmọ Neriah sì ṣe gẹ́gẹ́ bí gbogbo èyí tí wòlíì Jeremiah sọ fún, láti ka ọ̀rọ̀ Olúwa láti inú ìwé ní ilé Olúwa.

    11Nígbà tí Mikaiah ọmọ Gemariah ọmọ Ṣafani gbọ́ gbogbo àkọsílẹ̀ ọ̀rọ̀ Olúwa láti inú ìwé náà;

    15Wọ́n sì wí fún pé, "Jókòó, jọ̀wọ́ kà á sí etí wa!"Nígbà náà ni Baruku sì kà á ní etí wọn.

  11. Êxodo 35

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 35
    Mostrando versículos 9–32 de 35

    9òkúta óníkìsì àti òkúta tí a tò sí ẹ̀wù efodu àti ìgbàyà.

    18Èèkàn àgọ́ náà fún àgọ́ náà àti fún àgbàlá àti okùn wọn.

    32Láti máa ṣe aláràbarà iṣẹ́ ní ti wúrà, fàdákà àti idẹ,

  12. Deuteronômio 18

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 18
    Mostrando versículos 7–15 de 22

    7Nígbà náà ni ó lè máa ṣe ìránṣẹ́ ní orúkọ Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí àwọn ọmọ Lefi arákùnrin rẹ̀ ti ń dúró ṣe iṣẹ́ ìsìn níwájú Olúwa níbẹ̀.

    11tàbí afògèdè, tàbí jẹ́ a bá iwin gbìmọ̀ tàbí oṣó tàbí abókùúsọ̀rọ̀.

    1518.15-19: Ap 3.22,23; 7.37.Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò gbé wòlíì kan dìde gẹ́gẹ́ bí èmi láàrín àwọn arákùnrin rẹ. Tìrẹ ni kí o gbọ́.

  13. Jó 9

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 9
    Mostrando versículos 4–13 de 35

    4Ọlọ́gbọ́n nínú àwọn alágbára ní ipa ní Òun.Ta ni ó ṣe agídí sí i tí ó sì gbé fún rí?

    10Ẹni tí ń ṣe ohun tí ó tóbi jù àwárí lọ,àní ohun ìyanu láìní iye.

    13Ọlọ́run kò ní fa ìbínú rẹ̀ sẹ́yìn,àwọn onírànlọ́wọ́ ti Rahabu a sì tẹríba lábẹ́ rẹ̀.

  14. Romanos 9

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 9
    Mostrando versículos 12–30 de 33

    129.12: Gẹ 25.23.kì í ṣe nípa ti iṣẹ́, bí kò ṣe ti ẹni tí ń peni—a ti sọ fún un pé, "Ẹ̀gbọ́n ni yóò máa sin àbúrò."

    249.24: Ro 3.29.Àní àwa, tí ó ti pè, kì í ṣe nínú àwọn Júù nìkan, ṣùgbọ́n nínú àwọn Kèrí pẹ̀lú?

    30 9.30: Ro 3.22; 10.6,20; Ga 2.16; 3.24; Fp 3.9; Hb 11.7. Ǹjẹ́ kí ni àwa ó ha wí? Pé àwọn Kèrí, tí kò lépa òdodo, ọwọ́ wọn tẹ òdodo, ṣùgbọ́n òdodo tí ó ti inú ìgbàlà wá ni.

  15. Ezequiel 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 2–24 de 27

    2Mo sì ya ẹnu mi, ó sì mú mi jẹ ìwé kíká náà.

    8Ṣùgbọ́n bí i tiwọn lèmi náà yóò ṣe jẹ́ kí ojú àti ọkàn rẹ le.

    24Nígbà náà ni Ẹ̀mí wọ inú mi, tí ó sì tún gbé mi dúró. Ó sì wí fún mi pé, "Lọ, ti ara rẹ mọ́ inú ilé rẹ

  16. 1 Crônicas 28

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 28
    Mostrando versículos 14–21 de 21

    14Ó yàn ìwọ̀n wúrà fún gbogbo ohun èlò wúrà tí a ó lò níbi oríṣìí ìsìn, àti ìwọ̀n fàdákà fún gbogbo ohun èlò fàdákà tí a ó lò fún oríṣìí ìsìn,

    16Ìwọ̀n ti wúrà fun tábìlì, tábìlì fún àkàrà tí a yà sọ́tọ̀; ìwọ̀n fàdákà fún àwọn tábìlì fàdákà;

    21Ìpín àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi ti ṣetán fún gbogbo iṣẹ́ ilé Olúwa. Gbogbo ọkùnrin tí ó ní ìfẹ́ sí i tí ó sì ní òye oríṣìíríṣìí iṣẹ́. Yóò ràn ọ́ lọ́wọ́ nínú iṣẹ́ náà. Àwọn ìjòyè àti gbogbo àwọn ènìyàn yóò gbọ́rọ̀ sí gbogbo àṣẹ rẹ."

  17. Provérbios 4

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 4
    Mostrando versículos 20–26 de 27

    20Ọmọ mi, tẹ́tí sí ohun tí mo sọ;fetísílẹ̀ dáradára sí ọ̀rọ̀ mi.

    24Mú àrékérekè kúrò ní ẹnu rẹ;sì jẹ́ kí ọ̀rọ̀ ìsọkúsọ jìnnà réré sí ẹnu rẹ.

    26 4.26: (Gk): Hb 12.13. Kíyèsi ìrìn ẹsẹ̀ rẹsì rìn ní àwọn ọ̀nà tí ó dára nìkan.

  18. Gênesis 49

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 49
    Mostrando versículos 5–22 de 33

    5"Simeoni àti Lefi jẹ́ arákùnrin—idà wọn jẹ́ ohun èlò ogun alágbára.

    21"Naftali yóò jẹ́ abo àgbọ̀nríntí a tú sílẹ̀ tí ó ń bí ọmọ dáradára.

    22"Josẹfu jẹ́ àjàrà eléso,àjàrà eléso ní etí odò,tí ẹ̀ka rẹ̀ gun orí odi.

  19. Salmos 150

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 150
    Mostrando versículos 2–4 de 6

    2Ẹ yìn ín fún iṣẹ́ agbára rẹ̀.Ẹ yìn ín fún títóbi rẹ̀ tí ó tayọ̀.

    3Ẹ fi ohùn ìpè yìn ín.Ẹ fi ohun èlò orin yìn ín.

    4Ẹ fi ohun èlò orin àti ijó yìn ínfi ohun èlò orin olókùn àti ìpè yìn ín,

  20. Jeremias 13

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 13
    Mostrando versículos 3–27 de 27

    3Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá nígbà kejì,

    8Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá pé:

    27ìwà àgbèrè àti ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́,àìlójútì panṣágà rẹ!Mo ti rí ìwà ìríra rẹ,lórí òkè àti ní pápá.Ègbé ni fún ọ ìwọ Jerusalẹmu!Yóò ti pẹ́ tó tí o ó fi máa wà ní àìmọ́?"

Léxico (correspondência exata) Semântico (correspondência relacionada) Versículos omitidos Contexto do capítulo