Pular para o conteúdo
Publicidade

Êxodo 11

Ikú àwọn àkọ́

1 Nísinsin yìí, Olúwa sọ fún Mose èmi yóò ààrùn kan i orí Farao àti ilẹ̀ Ejibiti. Lẹ́yìn náà yóò jẹ́ ̀yin ó lọ kúrò níhìn-ín yìí, nígbà ó ṣe bẹ́̀ yóò yín jáde pátápátá. 2 Sọ fún àwọn ènìyàn náà tọkùnrin tobìnrin wọn béèrè fún ohun èlò fàdákà àti wúrà lọ́wọ́ aládùúgbò rẹ̀. 3 (Olúwa jẹ́ wọn ojúrere àwọn ará Ejibiti, pàápàá, Mose fúnra rẹ̀ di ènìyàn pàtàkì ilẹ̀ Ejibiti iwájú àwọn ìjòyè Farao àti iwájú àwọn ènìyàn pẹ̀).

4 Nígbà náà ni Mose , "Èyí ni ohun Olúwa sọ, ̀gànjọ́ òru èmi yóò la ilẹ̀ Ejibiti kọjá. 5 Gbogbo àkọ́ọmọkùnrin ó ilẹ̀ Ejibiti ni yóò kùú, bẹ̀rẹ̀ lórí àkọ́ọkùnrin Farao ó jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀, ó fi orí àkọ́ọmọkùnrin ti ẹrúbìnrin ń lọ ọlọ àti gbogbo àkọ́ẹran ̀sìn pẹ̀. 6 Igbe ẹkún ńlá yóò sọ jákèjádò gbogbo ilẹ̀ Ejibiti. Irú ohun búburú ṣẹlẹ̀ tún ni ṣẹlẹ̀ mọ́. 7 Ṣùgbọ́n láàrín àwọn ará Israẹli ajá lásán gbó àwọn ènìyàn tàbí àwọn ẹran wọn.Nígbà náà ni ̀yin yóò mọ̀ Olúwa ti fi ìyàtọ̀ sáàrín àwọn ará Ejibiti àti Israẹli. 8 Gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀ wọ̀nyí yóò tọ̀ , wọn yóò wólẹ̀ ni iwájú, mi wọn yóò máa , Lọ àti àwọn ènìyàn ó tẹ̀!Lẹ́yìn náà èmi yóò jáde." Nígbà náà ni Mose fi ìbínú jáde kúrò iwájú Farao.

9 Olúwa ti sọ fún Mose , "Farao yóò kọ̀ láti fetísílẹ̀ iṣẹ́ ìyanu le pọ̀ Ejibiti." 10 Mose àti Aaroni ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu wọ̀nyí níwájú Farao, ṣùgbọ́n Olúwa ọkàn Farao le, òun jẹ́ àwọn Israẹli jáde kúrò ni orílẹ̀-èdè rẹ̀.

Veja também