Àjọ ìrékọjá
1 12.1-13: Le 23.5; Nu 9.1-5; 28.16; De 16.1,2. Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni ni ilẹ̀ Ejibiti pé,
30 Farao àti àwọn ìjòyè rẹ̀ àti gbogbo àwọn ara Ejibiti dìde ní ọ̀gànjọ́ òru, igbe ẹkún ńlá sì gba gbogbo ilẹ̀ Ejibiti, nítorí kò sí ilé kan tí ó yọ sílẹ̀ tí ènìyàn kan kò ti kú.