Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 12

24 "pa ìlànà yìí mọ́ gẹ́gẹ́ ohun ó máa ṣe títí ayérayé láàrín yín àti àwọn ìran yín. 25 Nígbà ̀yin de ilẹ̀ Olúwa yóò fi fún un yín òun ti ṣe ìlérí, máa kíyèsi àjọ yìí. 26 ìgbà àwọn ọmọ yín béèrè lọ́wọ́ yín, ni ohun àjọ yìí túmọ̀ fún un yín?27 sọ fún wọn ni ìgbà náà, Ẹbọ ìrékọjá Olúwa ni, ẹni ó rékọjá ilé àwọn ọmọ Israẹli ni ìgbà ó kọlu àwọn ara Ejibiti. ó si da wa nígbà ti ó pa àwọn ara Ejibiti.’ " Àwọn ènìyàn tẹríba láti sìn.

Veja também